Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 16

Dafidi àti Ṣiba

1 Nígbà Dafidi fi díẹ̀ kọjá orí òkè náà, ó, Ṣiba ìránṣẹ́ Mefiboṣeti ń bọ̀ pàdé rẹ̀, òun àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ méjì a ti gàárì, àti igba ìṣù àkàrà lórí wọn, àti ọgọ́rùn-ún síírí àjàrà gbígbẹ, àti ọgọ́rùn-ún èso ̀rún, àti ìgò ọtí wáìnì kan.

2 Ọba fún Ṣiba , "ni wọ̀nyí?"

Ṣiba , "Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọ̀nyí ni fún àwọn ará ilé ọba láti máa gùn àti àkàrà yìí, àti èso ̀rún yìí ni fún àwọn ̀dọ́mọdékùnrin láti jẹ; àti ọtí wáìnì yìí ni fún àwọn aláàárẹ̀ ijù láti mu."

3 Ọba , "Ọmọ olúwa rẹ ?"

Ṣiba fún ọba , "ó, ó jókòó Jerusalẹmu; nítorí ó , Lónìí ni ìdílé Israẹli yóò ìjọba baba mi padà fún mi.’ "

4 Ọba fún Ṣiba , "ó, gbogbo nǹkan í ṣe ti Mefiboṣeti jẹ́ tìrẹ."

Ṣiba , "Mo túúbá, jẹ́ n oore-ọ̀fẹ́ lójú rẹ, olúwa mi ọba."

Ṣimei Dafidi

5 Dafidi ọba Bahurimu, ó, ọkùnrin kan ti ibẹ̀ jáde , láti ìdílé Saulu , orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ṣimei, ọmọ Gera, ó ń èébú o ń bọ̀. 6 Ó sọ òkúta Dafidi, àti gbogbo ìránṣẹ́ Dafidi ọba, àti gbogbo ènìyàn, gbogbo àwọn alágbára ọkùnrin lọ́wọ́ ̀tún rẹ̀ àti lọ́wọ́ òsì rẹ̀. 7 Báyìí ni Ṣimei nígbà ó ń yọ èébú, "Jáde, ìwọ ọkùnrin ̀jẹ̀, ìwọ ọkùnrin Beliali. 8 Olúwa gbogbo ̀jẹ̀ ìdílé Saulu padà orí rẹ, ipò ẹni ìwọ jẹ ọba; Olúwa ti fi ìjọba náà Absalomu ọmọ rẹ lọ́wọ́: ó, ìwà búburú rẹ ni ó èyí , nítorí ọkùnrin ̀jẹ̀ ni ìwọ."

9 Abiṣai ọmọ Seruiah fún ọba , "Èéṣe òkú ajá yìí fi ń olúwa mi ọba? Jẹ́ èmi kọjá, èmi bẹ̀ ́, èmi bẹ́ ́ lórí."

10 Ọba , "Kín ni èmi ṣe pẹ̀yín, ̀yin ọmọ Seruiah? ó ń èébú, nítorí Olúwa ti fún un , Dafidi!Ta ni yóò , Kín ni ìdí o fi ṣe bẹ́̀.’ "

11 Dafidi fún Abiṣai, àti fún gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , "ó, ọmọ mi ó ti inú mi , ń mi kiri, ǹjẹ́ mélòó mélòó ni ará Benjamini yìí yóò ṣe? Fi í sílẹ̀, jẹ́ o máa yan èébú; nítorí Olúwa ni ó sọ fún un. 12 Bóyá Ọlọ́run yóò wo ìpọ́njú mi, Olúwa yóò fi ìre san án fún mi ipò èébú rẹ̀ lónìí."

13 Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ ń lọ ̀, Ṣimei ń rìn òdìkejì òkè ó lẹ́gbẹ̀́ rẹ̀, ó ń yan èébú ó ti ń lọ, ó ń sọ ́ lókùúta, ó ń fọ́n erùpẹ̀. 14 Ọba, àti gbogbo àwọn ènìyàn ó ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ Jordani, ó rẹ̀ wọ́n, wọ́n sinmi níbẹ̀.

Huṣai farahàn Absalomu ẹni ó ìfẹ́ i

15 Absalomu àti gbogbo àwọn ènìyàn, àwọn ọkùnrin Israẹli Jerusalẹmu, Ahitofeli pẹ̀rẹ̀. 16 Ó ṣe, nígbà Huṣai ará Arki, ̀rẹ́ Dafidi tọ Absalomu , Huṣai fún Absalomu , "ọba ó pẹ́! ọba ó pẹ́."

17 Absalomu fún Huṣai , "Oore rẹ ̀rẹ́ rẹ ni èyí? Èéṣe ìwọ ̀rẹ́ rẹ lọ?"

18 Huṣai fún Absalomu , "Bẹ́̀ kọ́ nítorí ẹni Olúwa, àti gbogbo àwọn ènìyàn yìí, àti gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli yàn, tirẹ̀ lèmi ó jẹ́, òun lèmi ó jókòó. 19 Àti , ta ni èmi ó sìn? ha yẹ èmi ó máa sìn níwájú ọmọ rẹ̀? Gẹ́gẹ́ èmi ti ń sìn níwájú baba rẹ, bẹ́̀ ni èmi ó sìn níwájú rẹ."

Absalomu wọlé tọ àwọn obìnrin baba rẹ̀

20 Absalomu fún Ahitofeli , "ará yín gbìmọ̀ ohun àwa ó ṣe."

21 Ahitofeli fún Absalomu , "Wọlé tọ àwọn obìnrin baba rẹ lọ, ó fi sílẹ̀ láti máa ṣọ́ ilé, gbogbo Israẹli yóò gbọ́ , ìwọ di ẹni ìríra baba rẹ, ọwọ́ gbogbo àwọn ó lọ́dọ̀ rẹ yóò le." 22 Wọ́n tẹ́ àgọ́ kan fún Absalomu òrùlé; Absalomu wọlé tọ àwọn obìnrin baba rẹ̀ lójú gbogbo Israẹli.

23 Ìmọ̀ Ahitofeli ó máa ń gbà ni ìgbà náà, ó dàbí ẹni ènìyàn béèrè nǹkan lọ́wọ́ Ọlọ́run, bẹ́̀ ni gbogbo ìmọ̀ Ahitofeli fún Dafidi àti fún Absalomu .

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também