Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 10

Ògo kúrò nínú tẹmpili

1 10.1: If 4.2. Mo ó, mo ohun kan dàbí òkúta safire nínú òfúrufú lókè orí kérúbù, ìrísí ohun yìí dàbí ìtẹ́. 2 10.2: If 8.5.Olúwa sọ fún ọkùnrin wọ aṣọ funfun , "Lọ àárín àwọn kẹ̀kẹ́ lábẹ́ kérúbù. Bu ẹyin iná kúnwọ́ rẹ láàrín kérúbù, o fọ́n sórí ìlú náà." Ó lọ lójú mi.

3 Àwọn kérúbù dúró apá gúúsù tẹmpili nígbà ọkùnrin náà wọlé, ìkùùkuu bo inú àgbàlá. 4 Ògo Olúwa kúrò lórí àwọn kérúbù, ó bọ́ ibi ìloro tẹmpili. Ìkùùkuu bo inú tẹmpili, àgbàlá kún fún ìmọ́lẹ̀ àti ògo Olúwa. 5 A gbọ́ ariwo ìyẹ́ àwọn kérúbù yìí títí àgbàlá ìta gẹ́gẹ́ ìgbà Ọlọ́run Olódùmarè ń sọ̀rọ̀.

6 Nígbà Olúwa pàṣẹ fún ọkùnrin aláṣọ funfun yìí , "iná láàrín àwọn kẹ̀kẹ́, láàrín àwọn kérúbù," ó lọ dúró ṣẹ́gbẹ̀́ àwọn kẹ̀kẹ́ náà. 7 ̀kan nínú àwọn kérúbù nawọ́ ibi iná láàrín kérúbù yòókù. Ó lára rẹ, ó fi sínú ọwọ́ ọkùnrin aláṣọ funfun, òun náà gbà á, ó jáde lọ. 8 (Ohun dàbí ọwọ́ ènìyàn lábẹ́ ìyẹ́ àwọn kérúbù yìí.)

9 Nígbà mo , kíyèsí i, àwọn kẹ̀kẹ́ mẹ́rin lẹ́gbẹ̀́ àwọn kérúbù yìí, kẹ̀kẹ́ kọ̀̀kan lẹ́gbẹ̀́ kérúbù kọ̀̀kan; ìrí àwọn kẹ̀kẹ́ yìí ń tàn yanran àwọ̀ òkúta berili. 10 ti ìrísí wọn, gbogbo wọn jọra wọn; ̀kọ̀̀kan ìgbà kẹ̀kẹ́ kan nínú kẹ̀kẹ́ mìíràn. 11 Nígbà wọ́n ń lọ, wọ́n tẹ̀̀kan nínú ̀mẹ́rin àwọn kérúbù dojúkọ; àwọn kẹ̀kẹ́ náà yípadà àwọn kérúbù ti ń lọ. Àwọn kérúbù ń lọ ibi orí dojúkọ láì . 12 10.12: El 1.18; If 4.8.Gbogbo ara wọn àti ̀yìn, ọwọ́ wọn àti ìyẹ́ wọn, àti àwọn kẹ̀kẹ́ kún fún ojú yíkákiri kẹ̀kẹ́, àwọn mẹ́rẹ̀̀rin . 13 Mo gbọ́ wọ́n pe àwọn kẹ̀kẹ́ yìí ni "kẹ̀kẹ́ àjà." 14 10.14: El 1.10; If 4.7.̀kọ̀̀kan àwọn kérúbù yìí ni ojú mẹ́rin: ojú èkínní jẹ́ ojú kérúbù, ojú kejì jẹ́ ti ènìyàn, ojú kẹta jẹ́ ti kìnnìún nígbà ojú kẹrin jẹ́ ti ẹyẹ idì.

15 A gbé àwọn kérúbù sókè. Èyí ni àwọn ̀alààyè mo létí odò Kebari. 16 àwọn kérúbù yìí ń lọ àwọn kẹ̀kẹ́ ẹgbẹ́ wọn náà yóò lọ; bẹ́̀ ni àwọn kérúbù ìyẹ́ wọn láti dìde nílẹ̀, àwọn kẹ̀kẹ́ yìí kúrò lẹ́gbẹ̀́ wọn. 17 àwọn kérúbù dúró díẹ̀ àwọn kẹ̀kẹ́ náà yóò dúró jẹ́́; àwọn kérúbù dìde àwọn kẹ̀kẹ́ náà yóò dìde, nítorí ̀àwọn ̀alààyè yìí nínú wọn.

18 Ògo Olúwa kúrò níbi ìloro tẹmpili, ó dúró sórí àwọn kérúbù. 19 Àwọn kérúbù gbé ìyẹ́ wọn sókè, wọ́n kúrò nílẹ̀ lójú mi, wọ́n lọ pẹ̀kẹ̀kẹ́ wọn lẹ́̀kan náà. Wọ́n dúró níbi ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀ìlà-oòrùn ilé Olúwa, ògo Ọlọ́run Israẹli lórí wọn.

20 Àwọn wọ̀nyí ni ̀alààyè mo lábẹ́ Ọlọ́run Israẹli létí odò Kebari, mo mọ̀ kérúbù ni wọ́n. 21 ̀kọ̀̀kan wọn ojú mẹ́rin àti ìyẹ́ mẹ́rin, lábẹ́ ìyẹ́ wọn ni ohun jọ ọwọ́ ènìyàn . 22 Àfiwé ojú àti ìrísí wọn bákan náà pẹ̀àwọn mo létí odò Kebari. Olúkúlùkù wọn ń lọ ̀kánkán tààrà.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também