Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 13

Wòlíì èké gba ìdálẹ́bi

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn sọtẹ́lẹ̀ lòdì àwọn wòlíì Israẹli ń sọtẹ́lẹ̀, o sọ fún àwọn ń sọtẹ́lẹ̀ láti inú èrò ọkàn wọn, gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa! 3 Báyìí ni Olúwa Olódùmarè : Ègbé ni fún àwọn aṣiwèrè wòlíì ń tẹ̀̀ara wọn wọn nǹkan kan! 4 Israẹli àwọn wòlíì rẹ dàbí kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ nínú pápá. 5 ̀yin gòkè láti mọ odi ó ya ilé Israẹli wọ́n ba dúró gbọin ojú ogun ọjọ́ Olúwa. 6 Ìran àti àfọ̀ṣẹ wọn jẹ́ èké. Wọ́n , "Olúwa ," nígbà Olúwa rán wọn, síbẹ̀ wọ́n fẹ́ Olúwa ̀rọ̀ wọn ṣẹ. 7 ̀yin ha ti ìran asán, ̀yin ha ti fọ àfọ̀ṣẹ èké, nígbà ̀yin sọ , "Olúwa ," bẹ́̀ ni Èmi sọ̀rọ̀?

8 " Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè , Nítorí ̀rọ̀ asán àti ìran èké yín, mo lòdì yín: ni Olúwa Olódùmarè . 9 Ọwọ́ mi yóò lórí àwọn wòlíì ń ríran asán, ń sọ àfọ̀ṣẹ èké. Wọn nínú ìjọ àwọn ènìyàn mi, a ó yọ orúkọ wọn kúrò nínú àkọsílẹ̀ ilé Israẹli, bẹ́̀ ni wọn wọ ilẹ̀ Israẹli mọ́. Nígbà náà ni ̀yin yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa Olódùmarè.

10 " Wọ́n ti àwọn ènìyàn mi ṣìnà, wọ́n , "Àlàáfíà," nígbà àlàáfíà, nítorí àwọn ènìyàn mọ odi fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́, wọn a fi amọ̀ àìpò rẹ́ , wọn ó fi ẹfun kùn ún, 11 nítorí náà, sọ fún àwọn ń fi amọ̀ àìpò rẹ́ àti àwọn fi ẹfun kùn ún , odi náà yóò , ìkún omi òjò yóò , Èmi yóò rán òkúta yìnyín sọ̀kalẹ̀, ìjì líle yóò ya á lulẹ̀. 12 Nígbà odi náà , ǹjẹ́ àwọn ènìyàn wọn níbi yín , "Rírẹ́ rẹ́ , ibo ni ẹfun fi kùn ún ?"

13 " Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè , Nínú ìbínú gbígbóná mi, èmi yóò tu afẹ́fẹ́ líle e lórí nínú ìrunú mi, àti nínú ìbínú mi, òjò yóò rọ̀ púpọ̀ nínú ìbínú mi, àti yìnyín ńlá nínú ìrunú mi láti pa wọ́n run. 14 Èmi yóò ògiri fi amọ̀ àìpò rẹ́, èyí fi ẹfun kùn lulẹ̀ bi ìpìlẹ̀ rẹ yóò hàn jáde. Nígbà ti odi náà palẹ̀, a ó run yín sínú rẹ̀, ̀yin yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa. 15 Báyìí ni Èmi yóò ṣe lo ìbínú mi lórí odi yìí àti àwọn to fi amọ̀ àìpò rẹ́ , wọ́n fi ẹfun kùn ún. Èmi yóò sọ fún yín , "odi mọ́, bẹ́̀ ni àwọn rẹ́ náà mọ́. 16 Àwọn wòlíì Israẹli ń sọtẹ́lẹ̀ Jerusalẹmu, wọn ríran àlàáfíà i nígbà ti àlàáfíà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè ." 

17 "Nísinsin yìí, ọmọ ènìyàn, dojúkọ àwọn ọmọbìnrin ènìyàn rẹ wọ́n ń sọtẹ́lẹ̀ láti inú èrò ọkàn wọn, sọtẹ́lẹ̀ wọn 18 , Báyìí ni Olúwa Olódùmarè . Ègbé ni fún ̀yin obìnrin ń rán ìfúnpá òògùn ìgbọ̀nwọ́ àwọn ènìyàn, ń ṣe ìbòjú oríṣìíríṣìí fún orí oníkálùkù ènìyàn láti ṣọdẹ ọkàn wọn. ̀yin yóò wa dẹkùn fún ọkàn àwọn ènìyàn mi ? ̀yin yóò gba ọkàn ti ó tọ̀ yín ? 19 Nítorí ̀kúnwọ́ ọkà barle àti òkèlè oúnjẹ. ti pa àwọn yẹ pa, fi àwọn yẹ láààyè sílẹ̀ nípa irọ́ ń pa fún àwọn ènìyàn mi, èyí àwọn náà ń fetí .

20 " Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè . Mo lòdì ìfúnpá òògùn fi ń ṣọdẹ ọkàn ènìyàn káàkiri ẹyẹ, Èmi yóò ya á kúrò lápá yín, Èmi yóò ọkàn àwọn ènìyàn ń ṣọdẹ sílẹ̀. 21 Èmi yóò ya àwọn ìbòjú yín, láti gba àwọn ènìyàn mi lọ́wọ́ yín, wọn jẹ́ ìjẹ fún yín mọ́. Nígbà náà ni ̀yin yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa. 22 Nítorí ̀yin ti ba ọkàn àwọn olódodo jẹ́ pẹ̀irọ́ yín, nígbà Èmi ìbànújẹ́ wọn, àti nítorí ̀yin ti ọkàn àwọn ènìyàn búburú le, wọ́n ba à kúrò nínú ̀ibi wọn bi wọn yóò fi gba ̀wọn , 23 nítorí èyí, ̀yin í ríran èké, ̀yin fọ àfọ̀ṣẹ mọ́. Èmi yóò gba àwọn ènìyàn mi lọ́wọ́ yín. ̀yin yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também