Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 7

Òpin ti

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 7.2: If 7.1; 20.8."Ọmọ ènìyàn, báyìí ni Olúwa Olódùmarè ilé Israẹli:

" Òpin! Òpin ti

igun mẹ́rẹ̀̀rin ilẹ̀ náà!

3 Òpin báyìí,

èmi yóò ìbínú mi jáde ,

èmi yóò dájọ́ rẹ gẹ́gẹ́ ìwà rẹ,

èmi yóò san án fún gẹ́gẹ́ gbogbo ìwà ìríra rẹ.

4 Ojú mi i ,

bẹ́̀ ni èmi yóò ṣàánú;

ṣùgbọ́n èmi yóò san án fún gẹ́gẹ́ ̀rẹ

àti gbogbo ìwà ìríra láàrín rẹ.

Nígbà náà ̀yin yóò mọ̀ èmi ni Olúwa.

5 "Èyí ni Olúwa Olódùmarè :

" Ibi! Ibi kan ṣoṣo.

Kíyèsi, ó bọ̀ orí rẹ!

6 Òpin ti !

Òpin ti !

Ó ti dìde lòdì .

Kíyèsi, ó ti !

7 Ìparun ti sórí rẹ,

ìwọ ń gbé ilẹ̀ náà.

Àkókò náà ! Ọjọ́ wàhálà ti súnmọ́ etílé!

í ṣe ọjọ́ ariwo ayọ̀ lórí òkè.

8 Mo ṣetán láti ìbínú gbígbóná mi lórí

àti láti lo ìbínú mi lórí rẹ gẹ́gẹ́ gbogbo ̀rẹ,

èmi yóò lẹ́jọ́ gẹ́gẹ́ ̀rẹ

àti gẹ́gẹ́ ìwà ìríra rẹ ni èmi yóò san án fún .

9 Ojú mi i ,

Èmi ́ pẹ̀àánú;

èmi yóò san án fún gẹ́gẹ́ ̀rẹ

àti fún gbogbo ìwà ìríra láàrín rẹ.

" Nígbà náà o mọ̀ Èmi Olúwa lo kọlù yín.

10 " Ọjọ́ náà !

Kíyèsi ó ti !

Ìparun ti jáde,

̀ti tanná,

ìgbéraga ti rúdí!

11 Ìwà ipá ti di ̀ìwà búburú;

̀láti jẹ ẹni búburú ìyà.

nínú wọn yóò ṣẹ́,

tàbí nínú ̀pọ̀lọpọ̀ wọn,

nínú ọrọ̀ wọn,

ohun ó iye.

12 Àkókò náà !

Ọjọ́ náà ti !

òǹrajà ṣe yọ̀,

bẹ́̀ ni ki òǹtajà ṣe ṣọ̀fọ̀;

nítorí, ìbínú gbígbóná lórí gbogbo ènìyàn.

13 Nítorí òǹtajà yóò gbà padà

dúkìá èyí

níwọ̀n ìgbà ti àwọn méjèèjì láààyè.

Nítorí ìran kan gbogbo ènìyàn yìí

padà.

Nítorí ̀ṣẹ̀ wọn, ̀kan nínú wọn

yóò gba ara rẹ̀ .

14 " Wọ́n ti fọn ìpè ogun,

wọ́n pèsè ohun gbogbo sílẹ̀,

ṣùgbọ́n ẹni yóò lọ ojú ogun,

nítorí ìbínú gbígbóná mi ti lórí gbogbo ènìyàn.

15 Idà ìta,

àjàkálẹ̀-ààrùn àti ìyàn nílé,

idà yóò pa ẹni orílẹ̀-èdè,

àjàkálẹ̀-ààrùn àti ìyàn yóò pa ẹni ìlú.

16 Gbogbo àwọn ó bọ́ nínú wọn yóò sálà,

wọn yóò lórí òkè.

i àdàbà inú àfonífojì,

gbogbo wọn yóò máa ṣọ̀fọ̀,

olúkúlùkù nítorí àìṣedéédéé rẹ̀.

17 Gbogbo ọwọ́ yóò rọ,

gbogbo orúnkún yóò di aláìlágbára omi.

18 Wọn yóò wọ aṣọ ̀fọ̀,

̀yóò wọ́n mọ́lẹ̀,

ìtìjú yóò wọn,

wọn yóò irun wọn.

19 " Wọn yóò fàdákà wọn ojú pópó,

wúrà wọn yóò dàbí èérí

fàdákà àti wúrà wọn

le gbà wọ́n

ọjọ́ ìbínú gbígbóná Olúwa.

Wọn le jẹun tẹ́ ra wọn lọ́rùn

tàbí wọn kún ikùn wọn pẹ̀oúnjẹ

nítorí ó ti di ohun ìkọ̀sẹ̀ fún wọn.

20 Wọ́n ń ṣe ìgbéraga pẹ̀ohun ̀ṣọ́ wọn ó lẹ́,

wọn ti fi ṣe òrìṣà,

wọn tún ya àwòrán ìríra wọn níbẹ̀.

Nítorí náà, èmi yóò sọ àwọn nǹkan wọ̀nyí di aláìmọ́ fún wọn.

21 Èmi yóò fi àwọn nǹkan wọ̀nyí ṣe ìjẹ fún àjèjì

àti ìkógun fún àwọn ènìyàn búburú ayé,

wọn yóò sọ ́ di aláìmọ́.

22 Èmi yóò gbójú mi kúrò lára wọn,

àwọn ọlọ́ṣà yóò sọ ibi ìṣúra mi di aláìmọ́;

àwọn ọlọ́ṣà yóò wọ inú rẹ̀,

wọn yóò á jẹ́.

23 " Rọ ̀wọ̀n irin!

Nítorí ilẹ̀ náà kún fún ̀ṣẹ̀ ìtàjẹ̀ sílẹ̀,

ìlú náà kún fún ìwà ipá.

24 Èmi yóò orílẹ̀-èdè ti ó búburú jùlọ

láti jogún ilé wọn.

Èmi yóò fi òpin ìgbéraga àwọn alágbára,

ibi mímọ́ wọn yóò di bíbàjẹ́.

25 Nígbà ìpayà ,

wọn yóò àlàáfíà, lórí asán.

26 Wàhálà lórí wàhálà yóò ,

ìdágìrì lórí ìdágìrì.

Nígbà náà ni wọn yóò ìran lọ́dọ̀ wòlíì,

ṣùgbọ́n ̀kọ́ òfin yóò parun lọ́dọ̀ àlùfáà,

bẹ́̀ ni ìmọ̀ràn yóò ṣègbé lọ́dọ̀ àwọn àgbàgbà.

27 Ọba yóò ṣọ̀fọ̀,

ọmọ-aládé yóò láìní ìrètí,

ọwọ́ àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà yóò wárìrì.

Èmi yóò ṣe é fún wọn gẹ́gẹ́ ìṣe wọn,

èmi yóò ṣe ìdájọ́ wọn gẹ́gẹ́ ìgbékalẹ̀ wọn.

Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ èmi Olúwa.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também