Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 43

Ògo padà inú ilé Ọlọ́run

1 Lẹ́yìn náà ọkùnrin náà mi gba ti ẹnu-ọ̀ó dojúkọ ìhà ìlà-oòrùn, 2 43.2: El 1.24; If 1.15; 14.2; 19.6.mo ri ògo Ọlọ́run Israẹli ń bọ láti ìhà ìlà-oòrùn. Ohùn rẹ̀ dàbí híhó omi, ìtànṣán ògo rẹ̀ bo ilẹ̀. 3 Ó dàbí ìran mo , gẹ́gẹ́ ìran mo nígbà mo láti pa ìlú náà run; ìran náà ìran mo lẹ́bàá odò Kebari, mo dojú mi bolẹ̀. 4 Ògo Olúwa gba ̀o dojúkọ ìhà ìlà-oòrùn wọ inú ilé Ọlọ́run . 5 Mo ni ìrusókè ̀, ó mi lọ inú ilé ìdájọ́, kíyèsi ògo Olúwa kún inú ilé Ọlọ́run.

6 Nígbà ọkùnrin náà dúró ̀gbẹ́ mi, mo gbọ́ ẹnìkan ó mi sọ̀rọ̀ láti inú ilé Ọlọ́run. 7 Ó , "Ọmọ ènìyàn, èyí yìí ni ibi ìgúnwà mi àti ibi ó fún àtẹ́lẹsẹ̀ mi. Ibi yìí ni èmi yóò máa gbé àárín àwọn ọmọ Israẹli títí láéláé. Ilé Israẹli ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́ mọ́ láéláé àwọn tàbí àwọn ọba wọn nípa àgbèrè àti àwọn ère aláìlẹ́mìí àwọn ọba wọn ibi gíga. 8 Nígbà wọ́n ba gbé ìloro ilé wọn kángun ìloro ilé mi àti ìlẹ̀kùn wọn ̀gbẹ́ ìlẹ̀kùn mi, pẹ̀ògiri nìkan àárín èmi pẹ̀wọn, wọ́n ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́ pẹ̀ìwà ìríra wọn. Nígbà náà ni mo pa wọ́n run ìbínú mi. 9 Nísinsin yìí jẹ́ wọn ìwà àgbèrè wọn àti àwọn ère aláìlẹ́mìí àwọn ọba wọn kúrò ni iwájú mi, èmi yóò gbé àárín wọn láéláé.

10 "Ọmọ ènìyàn, ṣàpèjúwe ilé Ọlọ́run náà fún àwọn ènìyàn Israẹli ojú ̀ṣẹ̀ wọn, wọ́n jẹ́ wọn wo àwòrán ilé náà, 11 ojú gbogbo ohun wọn ti ṣe wọ́n, jẹ́ wọ́n mọ̀ àwòrán ilé Ọlọ́run náà wọ́n ṣe ó lẹ́sẹẹsẹ, àbájáde àti àbáwọlé rẹ̀ gbogbo àwòrán àti gbogbo òfin àti ìlànà rẹ̀. Kọ ìwọ̀nyí sílẹ̀ iwájú wọn wọn ó jẹ́ olóòtítọ́ si àwòrán rẹ̀, wọ́n tẹ̀gbogbo òfin rẹ̀.

12 "Èyí yìí òfin ilé Ọlọ́run náà. Gbogbo àyíká lórí òkè gíga yóò jẹ́ ibi mímọ́ jùlọ. èyí ni òfin tẹmpili náà.

Pẹpẹ ìrúbọ náà

13 "Ìwọ̀nyí ni wíwọ̀n pẹpẹ ìrúbọ gígùn ìgbọ̀nwọ́, ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan ni jíjìn, ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan ni ìbú, igun rẹ̀ yípo àti etí rẹ̀ jẹ́ ìbú àtẹ́lẹwọ́ kan. Èyí yìí ni gíga pẹpẹ ìrúbọ náà. 14 Láti ìsàlẹ̀ rẹ̀ ni ilẹ̀ títí ìsàlẹ̀ igun rẹ̀, ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ méjì ni gíga o jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan ìbú. Láti igun rẹ̀ ìsàlẹ̀ títí igun rẹ̀ ti òkè ó yípo pẹpẹ jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rin gíga, igun náà jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan ìbú. 15 Ibi ìdáná pẹpẹ ìrúbọ náà jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rin gíga, ìwo mẹ́rẹ̀̀rin yọrí jáde sókè láti ibi ìdáná. 16 Ibi ìdáná pẹpẹ náà jẹ́ igun mẹ́rin mẹ́rin lọ́gbọọgba, ìgbọ̀nwọ́ méjìlá gígùn, o jẹ ìgbọ̀nwọ́ méjìlá ìbú. 17 Igun ni apá òkè náà jẹ́ igun mẹ́rin lọ́gbọọgba, ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rìnlá gígùn, ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rìnlá ìbú, pẹ̀etí ó jẹ́ ìdajì ìgbọ̀nwọ́, ìsàlẹ̀ rẹ̀ jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan yípo. Àtẹ̀gùn pẹpẹ ìrúbọ náà dojúkọ ìlà-oòrùn."

18 Lẹ́yìn náà, ó sọ fún mi , "Ọmọ ènìyàn, èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè : Ìwọ̀nyí yóò jẹ́ òfin fún ìrúbọ ẹbọ sísun àti wíwọ̀n ̀jẹ̀ sórí pẹpẹ nígbà a mọ pẹpẹ tán. 19 ̀yin láti ̀dọ́ akọ màlúù gẹ́gẹ́ ẹbọ ìrékọjá fún àwọn àlùfáà, ó jẹ́ Lefi, ìdílé Sadoku ó agbègbè láti ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́ fún mi Olúwa Olódùmarè . 20 ni láti lára ̀jẹ̀ rẹ̀, fi sórí ìwo mẹ́rẹ̀̀rin ó lórí pẹpẹ, àti lórí igun mẹ́rẹ̀̀rin ìjókòó náà àti gbogbo etí rẹ̀ yípo, ìwọ yóò sọ pẹpẹ di mímọ́, ìwọ yóò ṣe ètùtù rẹ̀. 21 Ìwọ gbọdọ̀ akọ màlúù fún ìrékọjá, ìwọ yóò sun ún apá ibi a sàmì agbègbè ilé Ọlọ́run ìta ibi mímọ́.

22 "ọjọ́ kejì ìwọ yóò fi ewúrẹ́, òbúkọ aláìlábàwọ́n fún ẹbọ ̀ṣẹ̀, a gbọdọ̀ sọ pẹpẹ di mímọ́ gẹ́gẹ́ a ti ṣọ́ di mímọ́ pẹ̀akọ màlúù. 23 Nígbà ìwọ parí ìsọdimímọ́, ìwọ yóò fi ̀dọ́ akọ màlúù àti ̀dọ́ àgbò aláìlábàwọ́n láti inú agbo fún ìrúbọ. 24 Ìwọ yóò wọn lọ iwájú Olúwa, àwọn àlùfáà ni yóò fi iyọ̀ wọ́n wọn, wọn yóò fi wọ́n ẹbọ sísun Olúwa.

25 "Fún ọjọ́ méje, ìwọ láti pèsè akọ ewúrẹ́ kan lójoojúmọ́ fún ẹbọ ̀ṣẹ̀; ìwọ yóò pèsè ̀dọ́ akọ màlúù àti àgbò láti inú agbo, méjèèjì yóò jẹ́ aláìlábàwọ́n. 26 Fún ọjọ́ méje wọn yóò jẹ́ ètùtù fún pẹpẹ, wọn yóò sọ ́ di mímọ́; nípa bẹ́̀ wọn yóò á sọ́tọ̀. 27 ìparí ọjọ́ wọ̀nyí, láti ọjọ́ mẹ́jọ síwájú, àwọn àlùfáà ni yóò gbé àwọn ẹbọ sísun rẹ àti ẹbọ ìdàpọ̀ rẹ̀ kalẹ̀ lórí pẹpẹ. Lẹ́yìn náà, èmi yóò tẹ́wọ́gbà yín Olúwa Olódùmarè ."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também