Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 31

Òpépé igi Sedari ni Lebanoni

1 ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kẹta ọdún kọkànlá, ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn, sọ fún Farao ọba Ejibiti àti ìjọ rẹ̀:

" Ta a le fiwé ọláńlá?

3 Kíyèsi Asiria, ó jẹ́ igi kedari ni

Lebanoni ìgbà kan ,

pẹ̀àwọn ̀ka dáradára ó ṣẹ́ ìji bo igbó náà;

ó ga sókè,

òkè rẹ̀ lókè ni ewé ó nípọn .

4 Omi un dàgbàsókè:

orísun omi ó jinlẹ̀ o dàgbàsókè;

àwọn odo rẹ̀ ń sàn ìdí rẹ̀ ,

ó rán ìṣàn omi rẹ̀ gbogbo igi orí pápá.

5 Nítorí náà ó ga òkè fíofío

ju gbogbo igi orí pápá lọ;

̀ka rẹ̀ pọ̀ i

àwọn ̀ka rẹ̀ gùn,

wọn tẹ́ rẹrẹ nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ omi.

6 31.6: El 17.23; Da 4.12-21; Mt 13.32; Mk 4.32; Lk 13.19. Ẹyẹ ojú ̀run

kọ ilé ̀ka rẹ̀

gbogbo ẹranko igbó

ń bímọ abẹ́ ̀ka rẹ̀;

gbogbo orílẹ̀-èdè ńlá

ń gbé abẹ́ ìji rẹ̀.

7 Ọláńlá ẹwà rẹ̀ jẹ́,

pẹ̀títẹ́ rẹrẹ ̀ka rẹ̀,

nítorí gbòǹgbò rẹ̀ lọ ìsàlẹ̀

ibi ̀pọ̀lọpọ̀ omi .

8 31.8: (Gk): If 2.7. Àwọn igi kedari nínú ọgbà Ọlọ́run

è ó mọ́lẹ̀;

tàbí àwọn igi junifa

ṣe déédé pẹ̀̀ka rẹ̀,

tàbí a fi igi títẹ́ rẹrẹ ̀ka rẹ̀,

igi nínú ọgbà Ọlọ́run

ó rẹ̀ ẹwà rẹ̀.

9 Mo ó ẹwà

pẹ̀̀ka lọ́pọ̀lọ́pọ̀

fi jẹ́ ìlara àwọn igi gbogbo Edeni

í ṣe ọgbà Ọlọ́run.

10 " Nítorí náà, èyí yìí Olúwa Olódùmarè : Nítorí ó ga lọ sókè fíofío, ó gbé òkè rẹ̀ ga ju ewé ó nípọn lọ, àti nítorí gíga rẹ ó gbéraga, 11 mo fi alákòóso àwọn orílẹ̀-èdè náà lọ́wọ́, fún un láti fi ṣe ̀tọ́ fún un gẹ́gẹ́ ìwà búburú rẹ̀. Mo pa á ̀gbẹ́ kan, 12 àwọn orílẹ̀-èdè àjèjì aláìláàánú jùlọ e lulẹ̀, wọn fi kalẹ̀. Àwọn ̀ka rẹ̀ ṣubú sórí òkè àti gbogbo àárín àwọn òkè; àwọn ̀ka rẹ̀ ó ṣẹ sílẹ̀ gbogbo àlàfo jíjìn ilẹ̀. Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ilẹ̀ ayé jáde kúrò abẹ́ ìji rẹ̀ wọn fi sílẹ̀. 13 Gbogbo àwọn ẹyẹ ojú ̀run ṣe àtìpó ni orí igi ó ṣubú lulẹ̀ náà, gbogbo àwọn ẹranko igbó àárín ̀ka rẹ̀. 14 Nítorí náà igi mìíràn lẹ́gbẹ̀́ omi ó fi ìgbéraga ga sókè fíofío, yóò gbé sókè rẹ̀ ga ju ewé ó nípọn lọ. igi mìíràn ó omi bẹ́̀ ó ga bẹ́̀; gbogbo wọn ni a kádàrá ikú fún, fún ìsàlẹ̀ ilẹ̀, àárín àwọn alààyè ènìyàn, pẹ̀àwọn o lọ ̀gbun ìsàlẹ̀.

15 " Èyí ni Olúwa Olódùmarè : ọjọ́ ti a u isà òkú mo fi ̀fọ̀ ṣíṣe bo orísun omi jíjìn náà, mo àwọn ìṣàn omi rẹ̀ dúró, àti ̀pọ̀lọpọ̀ omi rẹ̀ a lọ́. Nítorí rẹ̀ mo fi ìwúwo ọkàn wọ Lebanoni aṣọ, gbogbo igi igbó gbẹ dànù. 16 Mo orílẹ̀-èdè wárìrì ìró ìṣubú rẹ̀ nígbà mo un ìsàlẹ̀ isà òkú pẹ̀àwọn ó lọ ̀gbun ìsàlẹ̀. Nígbà náà gbogbo igi Edeni, àṣàyàn àti èyí ó dára jùlọ nínú Lebanoni, gbogbo igi ó omi dáradára ni a nínú ni ayé ìsàlẹ̀. 17 Àwọn ó ń gbé abẹ́ òjìji rẹ̀, àwọn àjèjì rẹ àárín àwọn orílẹ̀-èdè náà, ti lọ ìsàlẹ̀ isà òkú pẹ̀rẹ̀, dídárapọ̀ mọ́ àwọn a fi idà pa.

18 " Èwo lára igi Edeni a fiwé dídán àti ọláńlá? Síbẹ̀ ìwọ, gan an sílẹ̀ pẹ̀àwọn igi Edeni lọ ìsàlẹ̀ ilẹ̀; ìwọ yóò sùn ni àárín àwọn aláìkọlà, pẹ̀àwọn a fi idà pa.

" Èyí yìí Farao àti ìjọ rẹ̀, Olúwa Olódùmarè .’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também