Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 27

Ìpohùnréré ẹkún fún Tire

1 ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn, pohùnréré ẹkún fún Tire. 3 Sọ fún Tire, a tẹ̀ẹnu-bodè Òkun, oníṣòwò àwọn orílẹ̀-èdè fún ̀pọ̀lọpọ̀ erékùṣù. Èyí yìí Olúwa Olódùmarè :

" Ìwọ Tire ,

"Ẹwà mi ."

4 Ààlà rẹ àárín Òkun;

àwọn ̀mọ̀rẹ ti ẹwà rẹ .

5 Wọn ṣe gbogbo pákó rẹ

igi junifa láti Seniri;

wọ́n ti igi kedari láti Lebanoni

láti fi ṣe òpó ọkọ̀ fún .

6 Nínú igi óákù ti Baṣani

wọn ti fi gbẹ́ ìtukọ̀ ̀rẹ̀;

ìjókòó rẹ ni wọn fi eyín erin ṣe pẹ̀

igi bokisi láti erékùṣù Kittimu .

7 ̀gbọ̀ dáradára aṣọ iṣẹ́ ọnà abẹ́rẹ́ láti Ejibiti

ni èyí ìwọ ta láti fi ṣe àsíá ọkọ̀ rẹ;

aṣọ aláró àti elése àlùkò

láti erékùṣù ti Eliṣa

ni èyí a fi ó.

8 Àwọn ará ìlú Sidoni àti Arfadi ni àwọn atukọ̀ rẹ̀

àwọn ọlọ́gbọ́n ̀rọ rẹ, ìwọ Tire,

ni àwọn atukọ̀ rẹ.

9 Àwọn àgbàgbà Gebali,

àti àwọn ọlọ́gbọ́n ibẹ̀,

nínú ọkọ̀ òṣìṣẹ́ atukọ̀ rẹ,

gbogbo ọkọ̀ ojú Òkun

àti àwọn atukọ̀ Òkun

pẹ̀rẹ láti dòwò pọ̀ pẹ̀rẹ̀.

10 " Àwọn ènìyàn Persia, Ludi àti Puti

nínú jagunjagun rẹ

àwọn ẹgbẹ́ ọmọ-ogun rẹ.

Wọ́n gbé asà àti àṣíborí wọn

sára ògiri rẹ,

wọn fi ẹwà rẹ hàn.

11 Àwọn ènìyàn Arfadi àti Heleki

lórí odi rẹ yíká;

àti àwọn akọni Gamadi,

nínú ilé ìṣọ́ rẹ.

Wọ́n fi àwọn asà wọn kọ ara odi rẹ;

wọn ti ẹwà rẹ .

12 " Tarṣiṣi ṣòwò pẹ̀rẹ torí ̀pọ̀lọpọ̀ ọrọ̀ ó ; wọn ṣe ìpààrọ̀ fàdákà, irin idẹ àti òjé fún ọjà títà rẹ̀.

13 " Àwọn ará Giriki, Tubali, Jafani àti Meṣeki, ṣòwò pẹ̀rẹ, wọ́n fi ẹrù àti ohun èlò idẹ ṣe pàṣípàrọ̀ fún ọrọ̀ rẹ.

14 " Àwọn ti ilé Beti-Togarma ṣe ìpààrọ̀ ẹṣin-ìṣiṣẹ́, ẹṣin ogun àti ìbáaka ṣòwò ọjà rẹ.

15 " Àwọn ènìyàn Dedani ni àwọn oníṣòwò rẹ, àti ̀pọ̀lọpọ̀ erékùṣù ni wọ́n jẹ́ oníbàárà rẹ̀; wọ́n eyín erin àti igi eboni san owó rẹ.

16 " Aramu ṣòwò pẹ̀nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ òwò rẹ̀; wọn ṣe ìpààrọ̀ òkúta iyebíye, òwú elése àlùkò, aṣọ iṣẹ́ ọnà abẹ́rẹ́, aṣọ ̀gbọ̀ dáradára, ìlẹ̀kẹ̀ iyùn pupa fún ọjà títà rẹ.

17 " Juda àti Israẹli, àwọn ni oníṣòwò rẹ; wọn ṣe ìpààrọ̀ ọkà, Minniti, àkàrà àdídùn; oyin, epo àti ìkunra olóòórùn dídùn ni wọ́n fi ọjà rẹ.

18 " Damasku ni oníṣòwò rẹ, nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ ohun ọjà ó ṣe àti ̀pọ̀lọpọ̀ ọrọ̀; ti ọtí wáìnì Helboni, àti irun àgùntàn funfun láti Sahari, 19 àti ìdẹ̀ ọtí wáìnì láti Isali, ohun wíwọ̀: irin dídán, kasia àti kálàmù ni àwọn ohun pàṣípàrọ̀ fún ọjà rẹ.

20 " Dedani ni oníṣòwò rẹ aṣọ ìjókòó-lẹ́sin fún ẹṣin-gígùn.

21 " Àwọn ará Arabia àti gbogbo àwọn ọmọ-aládé ìlú Kedari àwọn ni àwọn oníbàárà rẹ; ti ̀dọ́-àgùntàn, àgbò àti ewúrẹ́, nínú ìwọ̀nyí ni wọ́n ti jẹ́ oníbàárà rẹ.

22 " Àwọn oníṣòwò ti Ṣeba àti Raama, àwọn ni oníṣòwò rẹ; wọ́n ta onírúurú tùràrí olóòórùn dídùn dáradára ọjà rẹ, àti àwọn òkúta iyebíye àti wúrà.

23 " Harani àti Kanneh àti Edeni, àwọn oníṣòwò Ṣeba, Asiria àti Kilmadi, ni àwọn oníṣòwò rẹ. 24 Wọ̀nyí oníbàárà rẹ onírúurú nǹkan: aṣọ aláró, àti oníṣẹ́-ọnà àti àpótí aṣọ olówó iyebíye, a fi okùn , a fi igi kedari ṣe, nínú àwọn ilé-ìtajà rẹ.

25 " Àwọn ọkọ̀ Tarṣiṣi èrò

ọjà rẹ

a ti gbilẹ̀

a ti ṣe ́ lógo

àárín gbùngbùn Òkun.

26 Àwọn atukọ̀ rẹ ti

sínú omi ńlá.

Ṣùgbọ́n afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn yóò fọ́ wẹ́wẹ́

àárín gbùngbùn Òkun.

27 Ọrọ̀ rẹ, ọjà rẹ àti àwọn ohun títà rẹ,

àwọn ìṣúra rẹ, òṣìṣẹ́ ìtukọ̀ rẹ.

Àwọn oníbàárà rẹ àti gbogbo àwọn jagunjagun rẹ, ó nínú rẹ,

àti nínú gbogbo ẹgbẹ́ rẹ

ó àárín rẹ

yóò sínú àárín gbùngbùn Òkun

ọjọ́ ìparun rẹ.

28 Ilẹ̀ etí Òkun yóò

nítorí ìró igbe àwọn atukọ̀ rẹ.

29 Gbogbo àwọn alájẹ̀,

àwọn atukọ̀ Òkun

àti àwọn atọ́kọ̀ ojú Òkun;

yóò sọ̀ kálẹ̀ kúrò nínú ọkọ̀ wọn,

wọn yóò dúró lórí ilẹ̀.

30 Wọn yóò jẹ́ a gbọ́ ohùn wọn lòdì

wọn yóò sọkún kíkorò lórí

wọn yóò ku eruku orí ara wọn

wọn yóò ara wọn nínú eérú.

31 Wọn yóò irun orí wọn nítorí rẹ

wọn yóò wọ aṣọ yíya

wọn yóò pohùnréré ẹkún pẹ̀

ìkorò ọkàn nítorí rẹ

pẹ̀ohùn réré ẹkún kíkorò.

32 Àti nínú arò wọn ni wọn yóò pohùnréré ẹkún fún

wọn yóò pohùnréré ẹkún sórí rẹ, :

"Ta ni ó dàbí Tire

èyí ó parun àárín Òkun?"

33 Nígbà ọjà títà rẹ ti Òkun jáde

ìwọ tẹ́ ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè lọ́rùn

ìwọ fi ọrọ̀ ó pọ̀ àti àwọn ọjà títà rẹ

sọ àwọn ọba ayé di ọlọ́rọ̀.

34 ìsinsin yìí Òkun fọ túútúú

nínú ibú omi;

nítorí náà òwò rẹ àti gbogbo ẹgbẹ́ rẹ

àárín rẹ,

ni yóò ṣubú.

35 Ẹnu yóò ya gbogbo àwọn ti ń gbé

erékùṣù náà

jìnnìjìnnì yóò bo àwọn ọba wọn,

ìyọnu yóò han ojú wọn.

36 Àwọn oníṣòwò láàrín àwọn orílẹ̀-èdè dún ejò

ìwọ yóò jẹ́ ̀

ìwọ yóò ṣí mọ́ láéláé.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também