Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 33

Esekiẹli gẹ́gẹ́ bi olùṣọ́ Israẹli

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn sọ̀rọ̀ àwọn ènìyàn ilẹ̀ rẹ ó sọ fún wọn: Nígbà mo fi idà kọlu ilẹ̀ kan, àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà yan ̀kan lára àwọn ọkùnrin wọn láti jẹ́ alóre wọn, 3 ó i idà ń bọ̀ lórí ilẹ̀ náà, ó fọn ìpè láti kìlọ̀ fún àwọn ènìyàn, 4 nígbà náà ẹnikẹ́ni gbọ́ ìpè ṣùgbọ́n gbọ́ ìkìlọ̀, idà náà ó gba ̀rẹ̀, ̀jẹ̀ rẹ̀ yóò lórí ara rẹ̀. 5 Nítorí ó gbọ́ ohùn ìpè ṣùgbọ́n gbọ́ ìkìlọ̀, ̀jẹ̀ rẹ̀ yóò orí ara rẹ̀. ó gbọ́ ìkìlọ̀, òun ìbá ti gba ara rẹ̀ . 6 Ṣùgbọ́n alóre idà o ń bọ̀, fọn ìpè láti ki àwọn ènìyàn nílọ̀, idà náà , ó gba ̀̀kan nínú wọn, a yóò ọkùnrin náà lọ nítorí ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n èmi yóò béèrè ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ̀.’

7 "Ọmọ ènìyàn, èmi fi ṣe alóre fún ilé Israẹli; nítorí náà gbọ́ ̀rọ̀ mo sọ, o fún wọn ni ìkìlọ̀ láti ̀dọ̀ mi. 8 Nígbà ti mo sọ fún ẹni búburú , A! Ẹni búburú, ìwọ yóò dandan,ti ìwọ sọ̀rọ̀ síta láti i lọ́kàn padà kúrò ni ̀rẹ̀ gbogbo, ẹni búburú náà yóò nínú ̀ṣẹ̀ rẹ̀, èmi yóò béèrè ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ. 9 Ṣùgbọ́n ìwọ kìlọ̀ fún ẹni búburú láti padà kúrò ni ̀rẹ̀ gbogbo, òun ṣe bẹ́̀, òun yóò nítorí ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ìwọ ti gba ọkàn rẹ̀ .

10 "Ọmọ ènìyàn; sọ fún ilé Israẹli, Èyí yìí ìwọ sọ: "Àwọn ìrékọjá àti ̀ṣẹ̀ wa tẹ orí wa ba, àwa ń ṣòfò dànù nítorí wọn. wa ni a ṣe ?" 11 Sọ fún wọn , Níwọ́n ìgbà mo láààyè ni Olúwa Olódùmarè , èmi inú dídùn ikú ènìyàn búburú, ṣùgbọ́n dípò bẹ́̀, wọ̀nyí padà kúrò ̀wọn gbogbo wọn ó . ! Yípadà kúrò ni ̀búburú gbogbo! ìwọ yóò ̀yin ènìyàn Israẹli?

12 "Nítorí náà, ọmọ ènìyàn, sọ fún àwọn ènìyàn ilẹ̀ rẹ, Ìṣòdodo ti olódodo ènìyàn yóò gbà á nígbà òun ṣe àìgbọ́ràn, ìwà búburú ènìyàn búburú yóò o ṣubú nígbà ó padà kúrò nínú rẹ̀. olódodo ènìyàn ṣẹ̀, a ni jẹ́ ó nítorí òdodo rẹ̀ ti tẹ́lẹ̀.’ 13 mo sọ fún olódodo ènìyàn òun yóò , ṣùgbọ́n nígbà náà ó gbẹ́kẹ̀òdodo rẹ̀ ó ṣe búburú, a rántí nǹkan kan nínú iṣẹ́ òdodo o ti ṣe sẹ́yìn; òun yóò nítorí búburú ó ṣe. 14 mo sọ fún ènìyàn búburú , Ìwọ yóò dandan,ṣùgbọ́n ó yípadà kúrò nínú ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ti o ṣe èyí ó tọ́ àti èyí o yẹ. 15 ó mu ògo padà, o da ohun o ti gbé padà, ó tẹ̀òfin ó ń fún ni ìyè, ṣe búburú, òun yóò dandan; òun yóò . 16 A rántí ̀kan nínú ̀ṣẹ̀ ó ti . Ó ti ṣe èyí ó tọ àti èyí o yẹ; òun yóò dájúdájú.

17 "Síbẹ̀ àwọn ènìyàn ilẹ̀ rẹ sọ , ̀Olúwa tọ́.’ Ṣùgbọ́n ̀àwọn ó tọ́. 18 olódodo ènìyàn ba yípadà kúrò nínú òdodo rẹ̀, o ṣe búburú, òun yóò nítorí rẹ̀. 19 ènìyàn búburú yípadà kúrò nínú búburú rẹ̀, ó ṣe èyí ó tọ́ àti èyí ó yẹ, òun yóò nípa ṣíṣe bẹ́̀. 20 Síbẹ̀, ilé Israẹli ìwọ , ̀Olúwa ki i ṣe òtítọ́.’ Ṣùgbọ́n èmi yóò ṣe ìdájọ́ ẹnìkọ̀̀kan gẹ́gẹ́ ̀rẹ̀ ṣe ."

A ṣàlàyé ìṣubú Jerusalẹmu

21 ọjọ́ karùn-ún oṣù kẹwàá, ọdún kejìlá ìkólọ wa, ọkùnrin kan ó kúrò ni Jerusalẹmu sọ́dọ̀ mi, ó , "Ìlú ńlá náà ti ṣubú!" 22 ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ ó ku ̀la ẹni ó sálọ náà yóò , ọwọ́ Olúwa níbẹ̀ lára mi, o ya ẹnu mi ki ọkùnrin náà sọ́dọ̀ mi òwúrọ̀. Ẹnu ṣí, èmi yadi mọ́.

23 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 24 "Ọmọ ènìyàn, àwọn ènìyàn ó ń gbé nínú ìparun ilẹ̀ Israẹli ń , Abrahamu jẹ́ ọkùnrin kan, síbẹ̀ o gba ilẹ̀ ìní náà. Ṣùgbọ́n àwa pọ̀, lóòótọ́ a ti fi ilẹ̀ náà fún wa gẹ́gẹ́ ìní wa.25 Nítorí náà, sọ fún wọn , Èyí yìí Olúwa Olódùmarè : Níwọ́n ìgbà ̀yin jẹ ẹran pẹ̀̀jẹ̀ ni inú rẹ̀, ̀yin àwọn ère yín, ta ̀jẹ̀ sílẹ̀, ̀yin yóò ha gba ilẹ̀ náà? 26 ̀yin gbẹ́kẹ̀idà yín, ̀yin ṣe nǹkan ìríra, ẹnìkọ̀̀kan nínú yín ba á obìnrin aládùúgbò rẹ̀ jẹ́. ̀yin yóò ha gba ilẹ̀ náà?

27 "Sọ èyí fún wọn: Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè : mo ti láààyè, àwọn ó kúrò nínú ìparun yóò ti ipa idà ṣubú, àwọn ẹranko búburú yóò pajẹ, àwọn ó ilé ìṣọ́ àti inú ihò òkúta ni àjàkálẹ̀-ààrùn yóò pa. 28 Èmi yóò ilẹ̀ náà di ahoro, ̀ṣọ́ ńlá agbára rẹ̀ yóò mọ́, àwọn òkè Israẹli yóò di ahoro, ẹnikẹ́ni le á kọjá. 29 Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ èmi ni Olúwa, nígbà mo ilẹ̀ náà di ahoro nítorí gbogbo ohun ìríra wọ́n ti ṣe.

30 "tìrẹ, ọmọ ènìyàn, àwọn ènìyàn ìlú n sọ̀rọ̀ nípa rẹ ̀gbẹ́ ògiri àti ẹnu-ọ̀ilé wọn, wọ́n ń sọ ara wọn , gbọ́ iṣẹ́ ti a ran láti ̀dọ̀ Olúwa .31 Àwọn ènìyàn mi sọ́dọ̀ rẹ, gẹ́gẹ́ wọn ṣe ń ṣe, wọn jókòó níwájú rẹ láti fetísí ̀rọ̀ rẹ, ṣùgbọ́n wọn ìṣe. Ẹnu wọn ni wọ́n fi n sọ̀rọ̀ ìfọkànsìn, ṣùgbọ́n ọkàn wọn ìwọra èrè tọ́. 32 Nítòótọ́ lójú wọn, ìwọ jẹ́ ẹni kan ó ń kọrin ìfẹ́ pẹ̀ohun dídára àti ohun èlò orin kíkọ, nítorí wọ́n gbọ́ ̀rọ̀ rẹ ṣùgbọ́n wọn mu ìṣe.

33 "Nígbà gbogbo ìwọ̀nyí ṣẹ yóò ṣẹ dandan, nígbà náà wọn yóò mọ̀ wòlíì kan ti wa láàrín wọn ."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também