Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 14

Àwọn abọ̀rìṣà gba ìdálẹ́bi

1 Díẹ̀ nínú àwọn àgbàgbà Israẹli sọ́dọ̀ mi, wọ́n jókòó níwájú mi. 2 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ , 3 "Ọmọ ènìyàn, àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ti gbé òrìṣà kalẹ̀ sínú ọkàn wọn, wọ́n gbé àwọn ohun wọn ṣubú sínú ̀ṣẹ̀ síwájú wọn; Èmi yóò ha jẹ́ wọ́n béèrè lọ́wọ́ mi rárá ? 4 Nítorí náà, sọ fún wọn , Báyìí ni Olúwa Olódùmarè : ẹnikẹ́ni ilé Israẹli gbé òrìṣà ọkàn rẹ̀, tún gbé ohun ìkọ̀sẹ̀ síwájú rẹ̀, ó sọ́dọ̀ wòlíì, Èmi Olúwa fúnra mi ni yóò ẹni ó wa lóhùn gẹ́gẹ́ ìwà ìbọ̀rìṣà rẹ. 5 Èmi yóò ṣe èyí láti gba ọkàn àwọn ará Israẹli ti tẹ̀òrìṣà wọn lọ padà ̀dọ̀ mi.

6 "Nítorí náà sọ fún ilé Israẹli, Èyí ni ohun Olúwa Olódùmarè : ronúpìwàdà! yípadà kúrò lọ́dọ̀ òrìṣà yín, ̀yin kọ gbogbo ìwà ìríra yín sílẹ̀!

7 " ẹnikẹ́ni ilé Israẹli tàbí àlejò ń gbé ilẹ̀ Israẹli, ya ara rẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ mi, gbé òrìṣà rẹ̀ ọkàn rẹ̀, tún gbé ohun ni ṣubú sínú ̀ṣẹ̀ síwájú rẹ, lẹ́yìn èyí tún lọ sọ́dọ̀ wòlíì láti béèrè nǹkan lọ́wọ́ mi! Èmi Olúwa fúnra ara mi èmi yóò a lóhùn. 8 Èmi yóò lòdì si irú ọkùnrin bẹ́̀ lọ́òdì, Èmi yóò fi i ṣe àmì àti òwe. Èmi yóò e kúrò láàrín àwọn ènìyàn mi. Nígbà náà, ̀yin yóò mọ̀ èmi ni Olúwa.

9 " wọ́n tan wòlíì náà láti sọtẹ́lẹ̀, Èmi Olúwa tan wòlíì náà, Èmi yóò nawọ́ i, èmi yóò pa á run kúrò láàrín àwọn ènìyàn mi Israẹli. 10 Wọn yóò ru ̀bi ̀ṣẹ̀ wọnìjìyà kan náà ó fún wòlíì àti ẹni lọ béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀. 11 ilé Israẹli ba à ṣáko kúrò lọ́dọ̀ mi mọ, wọ́n ba à fi gbogbo ìrékọjá ba ara wọn jẹ́ mọ́. Ṣùgbọ́n wọ́n le jẹ́ ènìyàn mi, Èmi náà le jẹ́ Ọlọ́run wọn, ni Olúwa Olódùmarè .’ "

Àwọn aláìṣòdodo gba ìdájọ́

12 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 13 "Ọmọ ènìyàn orílẹ̀-èdè kan dẹ́ṣẹ̀ mi nípa ìwà àìṣòdodo, èmi yóò nawọ́ mi jáde wọn, láti ìpèsè oúnjẹ wọn, èmi yóò rán ìyàn wọn, èmi yóò pa ènìyàn àti ẹranko inú rẹ̀, 14 àwọn ọkùnrin mẹ́ta yìí. Noa, Daniẹli àti Jobu tilẹ̀ nínú rẹ, kìkì ̀ara wọn nìkan ni wọ́n fi òdodo wọn gbàlà, Olúwa Olódùmarè .

15 "Tàbí mo jẹ́ ẹranko búburú gba orílẹ̀-èdè náà kọjá, wọn á jẹ́ bẹ́̀ ó di ahoro, ẹni le gba ibẹ̀ kọjá torí ẹranko búburú yìí, 16 àwọn ọkùnrin mẹ́ta wọ̀nyí tilẹ̀ nínú rẹ̀, Olúwa Olódùmarè , wọn yóò gba ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin : àwọn nìkan ni a ó gbàlà, ṣùgbọ́n ilẹ̀ náà yóò di ahoro.

17 "Tàbí mo idà kọjá láàrín orílẹ̀-èdè náà mo , jẹ́ idà kọjá láàrín ilẹ̀ náà,mo ìbínú gbígbóná wọn lórí nípa ìtàjẹ̀ sílẹ̀, mo pa ènìyàn àti ẹranko inú rẹ. 18 àwọn ọkùnrin mẹ́ta yìí tilẹ̀ nínú rẹ̀, Olúwa Olódùmarè , mo ti , wọn ki yóò gba ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin , ṣùgbọ́n àwọn tìkára wọn nìkan ni a ó gbàlà.

19 "Tàbí mo rán àjàkálẹ̀-ààrùn si ilẹ̀ náà, ti mo si da ìrunú mi e lórí pẹ̀̀jẹ̀, láti ènìyàn àti ẹranko kúrò nínú rẹ̀, 20 tilẹ̀ jẹ́ Noa, Daniẹli àti Jobu nínú rẹ, mo ti láààyè ni Olúwa Olódùmarè , wọn le gba ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin wọn . Ara wọn nìkan ni ìwà òdodo wọn gbàlà.

21 "Nítorí báyìí ni Olúwa Olódùmarè , báwo ni yóò ti burú nígbà mo rán ìdájọ́ kíkan mi mẹ́rin sórí Jerusalẹmu, èyí ni idà àti ìyàn, ẹranko búburú àti àjàkálẹ̀-ààrùn láti pa àwọn ènìyàn àti ẹranko inú rẹ̀! 22 Síbẹ̀, yóò ṣẹ́àwọn díẹ̀, àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin a ó jáde nínú rẹ̀. Wọn yóò yin, ̀yin yóò ìwà àti ìṣe wọn, nígbà náà ni ̀yin yóò ìtùnú nípa àjálù mo sórí Jerusalẹmuàní gbogbo àjálù mo ti sórí rẹ̀. 23 Nígbà ̀yin ìwà àti ìṣe wọn, a ó yín nínú, nítorí ̀yin yóò mọ̀ èmi ṣe nǹkan kan láìnídìí, ni Olúwa Olódùmarè ."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também