Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 24

Ìkòkò ìdáná náà

1 ọdún kẹsànán, oṣù kẹwàá, ọjọ́ kẹwàá, ni ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn, kọ ọjọ́ náà sílẹ̀, ọjọ́ náà gan an, nítorí ọba Babeli náà ti da ojú ti Jerusalẹmu ọjọ́ yìí gan an. 3 pa òwe yìí fún ilé ọlọ́tẹ̀ náà, sọ fún wọn : Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè :

" Gbé ìkòkò ìdáná náà ka iná,

gbé e ka iná o da omi i nínú.

4 àwọn ègé ẹran a náà sínú rẹ̀,

gbogbo àwọn ègé ẹran ó tóbi, itan àti apá.

àwọn egungun ó dára sínú rẹ̀,

5 àwọn ó jọjú nínú agbo ẹran.

àwọn egungun abẹ́ rẹ̀;

jẹ́ ó dáradára

jẹ́ àwọn egungun náà bọ̀ nínú rẹ̀.

6 Nítorí báyìí Olúwa Olódùmarè :

" Ègbé ni fún ìlú ẹlẹ́jẹ̀ náà,

fún ìkòkò náà èérí rẹ̀ nínú rẹ̀,

èérí kúrò lójú rẹ̀!

ẹran náà jáde ekìrí ekìrí

ṣe ṣà wọ́n .

7 " Nítorí ̀jẹ̀ ó ta sílẹ̀ àárín rẹ̀;

à á orí àpáta kan lásán

á orí ilẹ̀,

níbi ti erùpẹ̀ yóò ti ó.

8 Láti à le jẹ́ ìbínú ó láti gbẹ̀san

mo da ̀jẹ̀ rẹ̀ orí àpáta kan lásán,

o ma á ni bíbò.

9 Nítorí náà báyìí ni Olúwa Olódùmarè :

" Ègbé ni fún ìlú ẹlẹ́jẹ̀ náà!

Èmi pàápàá yóò jẹ́ òkìtì iná náà tóbi.

10 Nítorí náà igi náà jọ i,

o fi iná i.

Ṣe ẹran náà dáradára,

fi tùràrí dùn ún;

o jẹ́ egungun náà jóná.

11 Lẹ́yìn náà gbé òfìfo ìkòkò náà lórí ẹyin iná

idẹ rẹ̀ gbóná, ó pọ́n

àti ki ìfófó rẹ̀ le di yíyọ́ nínú rẹ̀

èérí rẹ̀ le dànù.

12 Ó ti ba gbogbo akitiyan jẹ:

èérí rẹ̀ jáde kúrò lára rẹ̀,

èérí náà gan an yóò nínú iná.

13 " Nísinsin yìí èérí rẹ̀ ni ìwà ìfẹ́kúfẹ̀́ . Nítorí mo gbìyànjú láti wẹ̀ ́ mọ́, ṣùgbọ́n ìwọ mọ́ kúrò nínú ìwà ìfẹ́kúfẹ̀́ rẹ, a yóò tún wẹ̀ mọ́ kúrò nínú èérí rẹ, títí èmi yóò fi jẹ́ ìbínú mi balẹ̀ sórí rẹ̀.

14 " Èmi Olúwa ni ó sọ ́, yóò ṣe, èmi yóò ṣe é. Èmi yóò padà sẹ́yìn; bẹ́̀ ni èmi yóò i, bẹ́̀ ni èmi yóò ọkàn mi padà; gẹ́gẹ́ ̀rẹ, àti gẹ́gẹ́ iṣẹ́ rẹ, ni wọn yóò lẹ́jọ́, ni Olúwa Olódùmarè .’ "

Ìyàwó Esekiẹli

15 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 16 "Ọmọ ènìyàn, kíyèsi i, mo ìfẹ́ ojú rẹ kúrò ̀dọ̀ rẹ, nípa lílù kan. Ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ gbààwẹ̀, bẹ́̀ ni ìwọ gbọdọ̀ sọkún, bẹ́̀ ni omijé ojú rẹ gbọdọ̀ kán sílẹ̀. 17 ṣe sọkún, ṣe gbààwẹ̀ fún òkú. ̀orí rẹ, bọ bàtà ẹsẹ̀ rẹ, ṣe bo ètè ìsàlẹ̀ rẹ, ma ṣe jẹ oúnjẹ àwọn ń ṣọ̀fọ̀ ń jẹ gẹ́gẹ́ àṣà."

18 Báyìí ni mo sọ̀rọ̀ fún àwọn ènìyàn òwúrọ̀, àṣálẹ́ ìyàwó mi . òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, mo ṣe a ti pàṣẹ fún mi.

19 Lẹ́yìn náà àwọn ènìyàn bi léèrè , "Ṣe o ni sọ fún wa ohun ti nǹkan wọ̀nyí láti ṣe pẹ̀wa?"

20 Mo sọ báyìí fún wọn , "̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 21 Sọ fún ilé Israẹli, Báyìí Olúwa Olódùmarè : Kíyèsi i, èmi yóò sọ ibi mímọ́ mi di ibi àìmọ́ tayọ agbára yín, ìfẹ́ ojú yín, ìkáàánú yín, àti ọmọ yín ọkùnrin àti àwọn ọmọ yín obìnrin ̀yin fi sílẹ̀ sẹ́yìn yóò ṣubú nípa idà. 22 Ẹyin yóò ṣe mo ti ṣe. ̀yin yóò bo ìsàlẹ̀ ojú yín tàbí jẹ oúnjẹ ti àwọn ń ṣọ̀fọ̀ ń jẹ gẹ́gẹ́ àṣà. 23 ̀yin yóò fi àwọn ̀àwọn orí yín àti àwọn bàtà ni ẹsẹ̀ yín, ̀yin yóò ṣọ̀fọ̀ tàbí sọkún, ṣùgbọ́n ̀yin yóò ṣòfò dànù nítorí àwọn àìṣedéédéé yín, ̀yin yóò máa kérora láàrín ara yín. 24 Esekiẹli yóò jẹ àmì fún un yín; ̀yin yóò ṣe gẹ́gẹ́ òun ti ṣe. Nígbà èyí ṣẹlẹ̀, ̀yin yóò mọ̀ èmi ni Olúwa Olódùmarè.

25 "Pẹ̀lúpẹ̀ìwọ, Ọmọ ènìyàn, yóò ha jẹ́ , ọjọ́ náà, nígbà ti mo gba agbára wọn, ayọ̀ wọn àti ògo wọn, ìfẹ́ ojú wọn, ohun wọn gbé ọkàn wọn , àti àwọn ọmọ ọkùnrin wọn pẹ̀àwọn ọmọ obìnrin wọn kúrò lọ́dọ̀ wọn, 26 ọjọ́ náà ẹni ó sálà yóò tọ̀ ́ láti sọ ìròyìn náà fún . 27 ọjọ́ náà ẹnu rẹ yóò ṣí; ìwọ yóò sọ̀rọ̀, ìwọ yóò yadi mọ́. Báyìí ìwọ yóò jẹ́ àmì fún wọn; wọn yóò mọ̀ èmi Olúwa."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também