Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 5

Idà n bọ̀ sórí Jerusalẹmu

1 "Báyìí, ọmọ ènìyàn, ìdá ó o fi ṣe abẹ ìfárí onígbàjámọ̀, o fi irun orí àti irùngbọ̀n rẹ. Fi irun yìí sórí ìwọ̀n o pín in. 2 Nígbà ọjọ́ ìgbóguntì parí, sun ìdákan nínú ìdámẹ́ta irun yìí níná láàrín ìlú. ìdákan nínú mẹ́ta o fi idà ú káàkiri ìlú. o ìdákan yòókù sínú afẹ́fẹ́. Nítorí pẹ̀idà ni èmi yóò máa wọn . 3 Ṣùgbọ́n díẹ̀ nínú irun yìí o ta á mọ́ etí aṣọ rẹ. 4 Tún ju díẹ̀ nínú irun yìí sínú iná, o sun ún níná. Torí láti ibẹ̀ ni iná yóò ti jáde lọ gbogbo ilé Israẹli.

5 "Báyìí ni Olúwa Olódùmarè : Èyí Jerusalẹmu, mo gbé kalẹ̀ àárín àwọn Orílẹ̀-èdè, pẹ̀àwọn ìlú gbogbo o i . 6 Síbẹ̀ nínú ìwà búburú rẹ ó ti ṣọ̀tẹ̀ si òfin àti ìlànà mi ju àwọn orílẹ̀-èdè àti àwọn ilẹ̀ i lọ. Ó ti kọ òfin mi sílẹ̀, o pa ìlànà mi mọ́.

7 "Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè : Nítorí ̀yin ti ṣe àìgbọ́ràn ju àwọn orílẹ̀-èdè yín lọ, tẹ̀ìlànà mi tàbí o pa òfin mi mọ́. O tilẹ̀ túnṣe dáradára àwọn orílẹ̀-èdè .

8 "Nítorí náà báyìí ni Olúwa Olódùmarè : Èmi gan an lòdì , Jerusalẹmu, èmi yóò jẹ ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè . 9 Nítorí gbogbo ohun ìríra rẹ, èmi yóò ṣe ohun n ì ṣe láàrín rẹ àti èyí n í ṣe irú rẹ̀ mọ́. 10 Nítorí náà láàrín rẹ àwọn baba yóò máa jẹ ọmọ wọn, àwọn ọmọ náà yóò máa jẹ baba wọn. Èmi yóò jẹ ́ , èmi yóò àwọn ṣẹ́sínú ̀fúùfù. 11 Nítorí náà, Olúwa Olódùmarè , mo ṣe láààyè, nítorí ìwọ ti sọ ibi mímọ́ mi di àìmọ́ pẹ̀àwọn àwòrán ̀gbin àti àwọn ohun ìríra rẹ, èmi yóò ojúrere mi kúrò lára rẹ, èmi í da , bẹ́̀ ni èmi yóò ́ pẹ̀àánú mọ́. 12 Ìdámẹ́ta nínú àwọn ènìyàn rẹ yóò nípa àjàkálẹ̀-ààrùn tàbí ìyàn run wọ́n: ìdámẹ́ta yóò ṣubú nípa idà lẹ́yìn odi rẹ, èmi yóò ìdámẹ́ta yòókù sínú ̀fúùfù, èmi yóò máa fi idà wọn.

13 "Ìbínú mi yóò dúró, bẹ́̀ ni ìbínú gbígbóná mi yóò rọlẹ̀, èmi yóò ti gba ̀san mi. Nígbà mo parí ìbínú mi lórí wọn, wọn ó mọ̀ , Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀ nínú ìtara mi.

14 "Èmi yóò fi ́ ṣòfò, èmi yóò sọ ́ di ̀gàn fún àwọn orílẹ̀-èdè , àti lójú àwọn ń kọjá. 15 O ó di ̀gàn, ̀sín àti ̀kọ̀ àti ohun ̀àti ìyanu fún àwọn orílẹ̀-èdè , nígbà mo fìyà jẹ ́ nínú ìbínú àti nínú ìbínú gbígbóná mi. Èmi Olúwa ni ó sọ bẹ́̀. 16 Nígbà èmi ó rán ọfà búburú ìyàn wọn, èyí yóò jẹ́ fún ìparun wọn. Èmí èmi yóò rán run yín. Èmí yóò sọ ìyàn di púpọ̀ fún yín. Èmí yóò ṣẹ́ ̀oúnjẹ yín. 17 Èmi yóò rán ìyàn àti ẹranko búburú i yín, wọn yóò fi yín sílẹ̀ ni àìlọ́mọ. Àjàkálẹ̀-ààrùn àti ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò kọjá láàrín yín. Èmi yóò si idà sórí rẹ. Èmi Olúwa sọ bẹ́̀."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também