Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 30

Ìpohùnréré ẹkún fún Ejibiti

1 ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ : : 2 "Ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ o : Báyìí Olúwa Olódùmarè :

" Hu, o ,

"Ó ṣe fún ọjọ́ náà!"

3 Nítorí ọjọ́ náà súnmọ́ tòsí

àní ọjọ́ Olúwa súnmọ́ tòsí,

ọjọ́ ọjọ́ ìkùùkuu ṣú dúdú,

àsìkò ìparun fún àwọn kèfèrí.

4 Idà yóò sórí Ejibiti

ìrora ńlá yóò sórí Kuṣi.

Nígbà àwọn a pa yóò ṣubú Ejibiti

wọn yóò ọrọ̀ rẹ̀ lọ

ìpìlẹ̀ rẹ̀ yóò lulẹ̀.

5 Kuṣi àti Puti, Libia, Ludi àti gbogbo Arabia, Kubu àti àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà ó mulẹ̀ yóò ṣubú nípa idà pẹ̀Ejibiti.

6 " Èyí yìí Olúwa :

" Àwọn àlejò Ejibiti yóò ṣubú

agbára ìgbéraga rẹ yóò kùnà

láti Migdoli títí Siene,

wọn yóò ti ipa idà ṣubú nínú rẹ;

Olúwa Olódùmarè .

7 Wọn yóò

lára àwọn ilẹ̀ ó di ahoro,

ìlú rẹ yóò

ara àwọn ìlú ó di ahoro.

8 Lẹ́yìn náà wọn yóò mọ̀ èmi Olúwa,

nígbà mo gbé iná kalẹ̀ Ejibiti

gbogbo àwọn olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ parun.

9 " ọjọ́ náà oníṣẹ́ yóò ti ̀dọ̀ mi jáde nínú ọkọ̀ ojú omi láti dẹ́rùbà Kuṣi ó nínú àlàáfíà. Ìrora yóò sórí wọn gẹ́gẹ́ ti ọjọ́ ìparun Ejibiti. Kíyèsi i, ó .

10 " Báyìí ni Olúwa Olódùmarè :

" Èmi yóò òpin ̀gọ̀̀rọ̀ àwọn

ènìyàn Ejibiti láti ọwọ́ Nebukadnessari ọba Babeli.

11 Òun àti àwọn ológun rẹ̀

̀àwọn orílẹ̀-èdè

a o láti pa ilẹ̀ náà run.

Wọn yóò fa idà wọn yọ Ejibiti

ilẹ̀ náà yóò kún fún àwọn a pa.

12 Èmi yóò àwọn odò Naili gbẹ,

Èmi yóò ta ilẹ̀ náà fún àwọn ènìyàn búburú:

láti ọwọ́ àwọn àjèjì ènìyàn,

Èmi yóò jẹ́ ilẹ̀ náà àti gbogbo ohun ó nínú rẹ ṣòfò.

Èmi Olúwa ni ó ti sọ ́.

13 " Báyìí Olúwa Olódùmarè :

" Èmi yóò pa àwọn òrìṣà run,

Èmi yóò òpin ère gbígbẹ́ ni Memfisi.

ọmọ-aládé mọ́ Ejibiti,

Èmi yóò ìbẹ̀gba gbogbo ilẹ̀ náà.

14 Èmi yóò Paturosi di ahoro,

èmi yóò fi iná Ṣoani,

èmi yóò fi ìyà jẹ Tebesi.

15 Èmi yóò ìbínú mi jáde sórí Pelusiumu

ìlú odi Ejibiti

èmi yóò àkójọpọ̀ Tebesi kúrò.

16 Èmi yóò ti iná bọ Ejibiti

Pelusiumu yóò japoró ìrora.

Ìjì líle yóò Tebesi

Memfisi yóò ìpọ́njú ìgbà gbogbo.

17 Àwọn ̀dọ́mọkùnrin Heliopolisi àti Bubasiti

yóò ti ipa idà ṣubú

wọn yóò àwọn ìlú wọn ìgbèkùn.

18 Ojú ọjọ́ yóò ṣókùnkùn Tafanesi

nígbà mo àjàgà Ejibiti kúrò;

níbẹ̀ agbára iyì rẹ̀ yóò dópin

wọn yóò fi ìkùùkuu ó

àwọn abúlé rẹ wọn yóò lọ ìgbèkùn.

19 Nítorí náà, Èmi yóò ki ìjìyà sórí Ejibiti,

wọn yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa.’ "

20 ọjọ́ keje oṣù kìn-ín-ní ọdún kọkànlá ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ , 21 "Ọmọ ènìyàn, Èmi ti ṣẹ́ apá Farao ọba Ejibiti. A ì ì di apá náà papọ̀ láti mu ó san, a ti di i si àárín igi pẹlẹbẹ o ni agbára láti di idà . 22 Nítorí náà, báyìí Olúwa Olódùmarè : Èmi lòdì Farao ọba Ejibiti. Èmi yóò sẹ́ apá rẹ̀ méjèèjì, èyí ó dára àti èyí a ti ṣẹ́ pẹ̀, yóò idà bọ́ sọnù ọwọ́ rẹ̀. 23 Èmi yóò fọ́n àwọn ènìyàn Ejibiti àárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò wọn gbogbo ilẹ̀. 24 Èmi yóò apá ọba Babeli agbára, èmi yóò fi idà mi ọwọ́ rẹ, ṣùgbọ́n èmi yóò ṣẹ́ apá Farao, yóò kérora níwájú rẹ̀ ọkùnrin a àṣápa. 25 Èmi yóò apá ọba Babeli , ṣùgbọ́n apá Farao yóò rọ. Nígbà náà wọn yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa, nígbà mo idà mi ọwọ́ ọba Babeli yóò fi idà náà kọlu Ejibiti. 26 Èmi yóò fọ́n àwọn ara Ejibiti àárín orílẹ̀-èdè, èmi yóò wọn àárín orílẹ̀-èdè, èmi yóò wọn gbogbo ilẹ̀. Nígbà náà wọn yóò mọ̀ èmi ni Olúwa."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também