Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 20

Ìwà ọlọ́tẹ̀ Israẹli

1 ọjọ́ kẹwàá, oṣù karùn-ún ọdún keje, díẹ̀ nínú àwọn àgbàgbà Israẹli wádìí lọ́wọ́ Olúwa, wọn jókòó níwájú mi.

2 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ , 3 "Ọmọ ènìyàn, sọ fún àwọn àgbàgbà Israẹli, ó fún wọn , Báyìí Olúwa Olódùmarè , ṣe ki wádìí lọ́dọ̀ mi ni ṣe ? mo ti láààyè, Olúwa Olódùmarè , Èmi yóò gbà wádìí lọ́dọ̀ mi.

4 "Ìwọ fẹ́ dájọ́ wọn ? Ìwọ fẹ́ dájọ́ wọn ọmọ ènìyàn? Nítorí náà fi gbogbo ìwà ìríra baba wọn wọ́n lójú, 5 ó sọ fún wọn , Báyìí Olúwa Olódùmarè , ọjọ́ mo yàn Israẹli, mo gbé ọwọ́ mi sókè nínú ìbúra àwọn ọmọ ilé Jakọbu, mo fi ara mi hàn wọn Ejibiti, mo gbé ọwọ́ mi sókè nínú ̀jẹ́ , "Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín." 6 ọjọ́ náà mo lọ búra fún wọn , èmi yóò wọn jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti lọ ilẹ̀ ti mo ti sílẹ̀ fún wọn, ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti oyin, ilẹ̀ ó lẹ́jùlọ láàrín àwọn ilẹ̀ yòókù. 7 Mo fún wọn , "olúkúlùkù nínú yín gbé ìríra ojú rẹ̀ kúrò, sọ ara yín di àìmọ́ pẹ̀àwọn òrìṣà Ejibiti, èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín."

8 " Ṣùgbọ́n wọn ṣọ̀tẹ̀ mi wọn gbọ́rọ̀, wọn gbé àwòrán ìríra wọ́n dojúkọ kúrò níwájú wọn bẹ́̀ ni wọn si kọ̀ àwọn òrìṣà Ejibiti sílẹ̀, torí náà mo sọ èmi yóò ìbínú gbígbóná mi wọn lórí, èmi yóò jẹ́ ìbínú mi sẹ̀ lórí wọn ilẹ̀ Ejibiti. 9 Ṣùgbọ́n nítorí orúkọ mi, mo ṣe ohun jẹ́ orúkọ mi bàjẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè wọn ń gbé láàrín wọn, lójú àwọn ẹni mo ti fi ara hàn fún ara Israẹli nípa mímú wọn jáde ilẹ̀ Ejibiti. 10 Nítorí náà, mo wọn jáde ilẹ̀ Ejibiti mo wọn sínú aginjù. 11 Mo fún wọn ni òfin mi, mo fi àwọn òfin mi hàn wọ́n; nítorí ẹni ṣe wọ́n yóò nípa wọn. 12 Bẹ́̀ ni mo fún wọn ọjọ́ ìsinmi gẹ́gẹ́ àmì láàrín àwọn àti èmi, wọn mọ̀ èmi ni Olúwa sọ wọn di mímọ́.

13 " Síbẹ̀; ilé Israẹli ṣọ̀tẹ̀ nínú aginjù. Wọn tẹ̀àṣẹ mi, wọn kọ àwọn òfin mi sílẹ̀ ó tilẹ̀ jẹ́ ẹni pa á mọ́ yóò nínú rẹ̀. Wọn sọ ọjọ́ ìsinmi mi di aláìmọ́ lọ́pọ̀lọ́pọ̀. Nítorí náà, mo sọ èmi yóò ìbínú gbígbóná mi sórí wọn, èmi yóò pa wọ́n run nínú aginjù. 14 Ṣùgbọ́n nítorí orúkọ mi, mo ṣe ohun orúkọ mi bàjẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè mo wọn jáde. 15 Nítorí náà, mo tún gbọ́wọ́ mi sókè ìbúra fún wọn nínú aginjù , èmi yóò wọn ilẹ̀ mo fi fún wọnilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti oyin, ilẹ̀ ó lẹ́jùlọ láàrín àwọn ilẹ̀ yòókù. 16 Nítorí , wọn kọ òfin mi sílẹ̀, wọn tẹ̀àṣẹ mi, wọn sọ ọjọ́ ìsinmi mi aláìmọ́. Nítorí tọkàntọkàn ni wọn ń tẹ̀òrìṣà wọn. 17 Síbẹ̀síbẹ̀ mo wọ́n pẹ̀àánú, ń pa wọ́n run tàbí òpin wọn nínú aginjù. 18 Ṣùgbọ́n mo sọ fún àwọn ọmọ wọn nínú aginjù , "ṣe rìn ìlànà àwọn baba yín, ṣe pa òfin wọn mọ́, ṣe ara yín jẹ́ pẹ̀òrìṣà wọn. 19 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, tẹ̀àṣẹ mi, ó pa òfin mi mọ́. 20 ya ọjọ́ ìsinmi mi mímọ́ ó jẹ́ àmì láàrín wa, ki mọ̀ èmi Olúwa Ọlọ́run yín."

21 " Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ náà ṣọ̀tẹ̀ mi. Wọn tẹ̀àṣẹ mi, wọn pa òfin mi mọ́ o tilẹ̀ jẹ́ ẹni tẹ̀àwọn òfin yìí, yóò nínú rẹ̀, wọ́n tún sọ ọjọ́ ìsinmi mi di aláìmọ́. Nítorí náà, mo sọ èmi yóò ìbínú mi lórí wọn, Èmi yóò ìbínú gbígbóná mi sórí wọn ni aginjù. 22 Síbẹ̀síbẹ̀ mo dáwọ́ dúró, nítorí orúkọ mi, mo ṣe ohun ba orúkọ mi jẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè ti mo wọn jáde lójú wọn. 23 Bẹ́̀ ni pẹ̀ọwọ́ ti mo gbé sókè wọn, mo búra fún wọn nínú aginjù èmi yóò wọn ka àárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò fọ́n wọn káàkiri ilẹ̀ gbogbo, 24 nítorí wọn pa òfin mi mọ́, wọn tún kọ àṣẹ mi sílẹ̀, wọn tún sọ ọjọ́ ìsinmi mi di aláìmọ́. Ojú wọn ara òrìṣà baba wọn. 25 Èmi náà fi wọn fún ìlànà dára àti òfin wọn le e nípa rẹ̀; 26 mo jẹ́ ó sọ wọn di aláìmọ́ nípa ̀bùn nípa fífi àkọ́ọmọ wọn ẹbọ sísun, àkọ́wọn la iná kọjá, èmi sọ wọ́n di ahoro, wọn le mọ̀ èmi ni Olúwa.

27 "Nítorí náà, Ọmọ ènìyàn, sọ fún ilé Israẹli ó fún wọn , Èyí ohun ti Olúwa Olódùmarè , nínú èyí baba yín ti sọ̀rọ̀-òdì mi, nípa kíkọ̀ sílẹ̀. 28 Nítorí nígbà mo wọn ilẹ̀ náà, mo gbé ọwọ́ mi sókè láti fi í fún wọn, nígbà náà ni wọ́n olúkúlùkù òkè gíga, àti gbogbo igi bíbò, wọ́n ẹbọ wọn níbẹ̀, wọ́n gbé ìmúnibínú ọrẹ wọ́n kalẹ̀ níbẹ̀; níbẹ̀ pẹ̀ni wọ́n ṣe òórùn dídùn wọn, wọ́n ta ohun ọrẹ mímu sílẹ̀ níbẹ̀. 29 Nígbà náà ni mo fún wọn , ibi gíga ̀yin lọ yìí?’ " (Orúkọ rẹ̀ ni a ń Bama di òní yìí.)

Ìdájọ́ Àti Ìmúpadàbọ̀sípò

30 "Nítorí náà sọ fún ilé Israẹli , Èyí ohun Olúwa Olódùmarè , ṣé o fẹ́ ba ara rẹ jẹ́ bi àwọn baba rẹ ṣe ṣe, tiwọn ń ṣe àgbèrè nípa títẹ̀àwọn àwòrán ìríra? 31 Nígbà ̀yin san ọrẹ yìí, ìrúbọ ọmọkùnrin ọmọ yín, ọmọ yin la iná kọjá, ̀yin ń tẹ̀síwájú láti ba ara yín jẹ́ pẹ̀àwọn òrìṣà yín títí di òní yìí, ̀yin yóò ha jẹ wádìí lọ́dọ̀ mi, ìwọ ilé Israẹli? mo ti láààyè, Olúwa Olódùmarè , Èmi ki yóò jẹ́ wádìí lọ́dọ̀ mi.

32 " ̀yin , "Àwa fẹ́ dàbí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù, àwọn ènìyàn ayé, ń bọ igi àti òkúta." Ṣùgbọ́n ohun ti ni lọ́kàn ṣẹ rárá. 33 mo ti láààyè, Olúwa Olódùmarè , Èmi yóò jẹ ọba lórí yín pẹ̀ọwọ́ agbára èmi yóò jáde pẹ̀ìtújáde ìbínú gbígbóná mi. 34 Èmi yóò si yín jáde kúrò láàrín àwọn ènìyàn, èmi yóò ṣà yín jọ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè a fọ́n yín pẹ̀ọwọ́ agbára àti apá nínà èmi yóò jáde àti pẹ̀ìtújáde ìbínú gbígbóná ni. 35 Èmi yóò si yín aginjù àwọn orílẹ̀-èdè, níbẹ̀ ni ojúkójú ni èmi yóò ṣe ìdájọ́ e yín lórí. 36 mo ṣe ṣe ìdájọ́ àwọn baba yín nínú aginjù nílẹ̀ Ejibiti, bẹ́̀ ni èmi yóò ṣe ìdájọ́ yín Olúwa Olódùmarè . 37 Èmi yóò kíyèsi i yín mo ti un yín kọjá lábẹ́ ̀, èmi yóò yín abẹ́ ìdè májẹ̀. 38 Èmi yóò si ṣa àwọn ọlọ̀tẹ̀ kúrò láàrín yín, àti àwọn o re òfin kọjá, èmi yóò mu wọn jáde kúrò ni ilẹ̀ tiwọn gbé ṣe àtìpó, wọn ki yóò si wọ ilẹ̀ Israẹli. Nígbà náà ̀yin yóò mọ̀ , èmi Olúwa.

39 " ̀yin, ilé Israẹli, èyí ni ohun Olúwa Olódùmarè : olúkúlùkù yín lọ máa sìn òrìṣà rẹ̀, ṣùgbọ́n lẹ́yìn èyí, ̀yin yóò gbọ́ tèmi, ̀yin i orúkọ mímọ́ mi jẹ́ pẹ̀ọrẹ àti àwọn òrìṣà yín mọ́. 40 Nítorí lórí òkè mímọ́ mi, lórí òkè gíga Israẹli, ni Olúwa Olódùmarè , níbẹ̀ ni ilẹ̀ náà gbogbo ilé Israẹli yóò sìn ; èmi yóò tẹ́wọ́ gba wọ́n níbẹ̀. Níbẹ̀ èmi yóò béèrè ọrẹ àti ̀bùn nínú àkọ́so yín pẹ̀gbogbo ẹbọ mímọ́ yín. 41 Èmi yóò tẹ́wọ́ gbà yín gẹ́gẹ́ tùràrí olóòórùn dídùn nígbà mo ba yín jáde láàrín àwọn orílẹ̀-èdè a fọ́n yín , èmi yóò fi ìwà mímọ́ mi hàn láàrín yín lójú àwọn orílẹ̀-èdè. 42 Nígbà náà ni o mọ̀ èmi Olúwa, nígbà mo yín wa ilẹ̀ Israẹli; ilẹ̀ mo gbọ́wọ́ sókè nínú ̀jẹ́ láti fún àwọn baba yín. 43 20.43: El 6.9; 36.31.Níbẹ̀ ni ó wa rántí ìwà àti gbogbo ìṣesí yín, èyí ̀yin fi sọ ara yín di aláìmọ́, ̀yin yóò kórìíra ara yín fún gbogbo ibi ̀yin ti ṣe. 44 Nígbà náà ̀yin yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa, nígbà mo hùwà yín nítorí orúkọ mi ni, ń hùwà yín gẹ́gẹ́ ̀ibi àti ìwà ìríra yín. ̀yin ilé Israẹli, ni Olúwa Olódùmarè .’ "

Sọtẹ́lẹ̀ lòdì ìhà gúúsù

45 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 46 "Ọmọ ènìyàn, dojúkọ ìhà gúúsù; wàásù lòdì gúúsù ìwọ sọtẹ́lẹ̀ igbó ilẹ̀ gúúsù. 47 Sọ fún igbó ìhà gúúsù : Gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa. Èyí ohun Olúwa Olódùmarè : Kíyèsi í, èmi yóò iná kan nínú rẹ̀, yóò olúkúlùkù igi tútù nínú rẹ̀, àti olúkúlùkù igi gbígbẹ. Jíjò ọwọ́ iná náà yóò ṣé é pa, àti gbogbo ojú láti gúúsù àríwá ni a ó sun nínú rẹ̀. 48 Gbogbo ènìyàn yóò mọ̀ , Èmi Olúwa ni ó a, a yóò le è pa á.’ "

49 Nígbà náà ni mo , "Háà! Olúwa Olódùmarè! Wọn ń fún mi , í wa ṣe òwe lo ń pa ?’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também