Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 25

Àsọtẹ́lẹ̀ òdì Ammoni

1 25.1-7: El 21.28-32; Jr 49.1-6; Am 1.13-15; Od 12; Sf 2.8-11. ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn, kọ ojú rẹ àwọn ará Ammoni ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ wọn. 3 fún àwọn ará Ammoni , gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa Olódùmarè ó . Nítorí ìwọ , "Á !" ibi mímọ́ mi nígbà ó di àìlọ́wọ̀ àti orí ilẹ̀ Israẹli nígbà ó di ahoro; àti ilẹ̀ Juda, nígbà wọ́n lọ ìgbèkùn, 4 kíyèsi i, nítorí náà ni èmi yóò fi fi àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn lọ́wọ́ ni ohun ìní. Wọn yóò gbé ààfin wọn kalẹ̀ nínú rẹ, wọn yóò gbé ibùgbé wọn nínú rẹ, wọn yóò jẹ èso rẹ, wọn yóò mu wàrà rẹ. 5 Èmi yóò sọ Rabba di ibùjẹ, fún àwọn ìbákasẹ àti àwọn ọmọ Ammoni di ibùsùn fún agbo ẹran. Nígbà náà ni ̀yin yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa. 6 Nítorí báyìí ni Olúwa Olódùmarè . Nítorí ìwọ pàtẹ́wọ́, ìwọ jan ẹsẹ̀ mọ́lẹ̀, ìwọ ń yọ̀ pẹ̀gbogbo àrankàn rẹ ilẹ̀ Israẹli 7 nítorí náà, èmi yóò na ọwọ́ mi , èmi yóò fi fún àwọn aláìkọlà fún ìkógun. Èmi yóò kúrò láàrín àwọn ènìyàn, èmi yóò jẹ́ o parun kúrò ni ilẹ̀ gbogbo. Èmi yóò pa ́ run, ìwọ yóò mọ̀ èmi ni Olúwa.’ "

Àsọtẹ́lẹ̀ òdì Moabu

8 25.8-11: Isa 15–16; 25.10-12; Jr 48; Am 2.1-3; Sf 2.8-11. "Báyìí ni Olúwa Olódùmarè : Nítorí Moabu àti Seiri sọ , "ó, ilé Juda ti dàbí gbogbo àwọn kèfèrí," 9 nítorí náà, Èmi yóò ṣí Moabu sílẹ̀ láti àwọn ìlú gbogbo ó ààlà rẹ̀, ògo ilẹ̀ náà, Beti-Jeṣimoti, Baali-Meoni àti Kiriataimu. 10 Èmi yóò fi Moabu pẹ̀àwọn ará Ammoni àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn ìní, a á rántí àwọn ará Ammoni láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo. 11 Èmi yóò ìdájọ́ sẹ Moabu lára, wọn yóò mọ̀ èmi ni Olúwa.’ "

Àsọtẹ́lẹ̀ òdì Edomu

12 25.12-14: El 35; Isa 34; 63.1-6; Jr 49.7-22; Am 1.11-12; Ml 1.2-5. "Báyìí ni Olúwa Olódùmarè : Nítorí Edomu gbẹ̀san lára ilé Juda, ó jẹ̀bi gidigidi nípa ṣíṣe bẹ́̀, 13 nítorí náà báyìí Olúwa Olódùmarè : Èmi yóò na ọwọ́ mi sórí Edomu èmi yóò pa àwọn ènìyàn àti àwọn ẹranko rẹ̀. Èmi yóò fi ṣófo láti Temani Dedani yóò ti ipa idà ṣubú. 14 Èmi yóò gbẹ̀san lára Edomu láti ọwọ́ àwọn ènìyàn mi Israẹli, wọn ṣe Edomu gẹ́gẹ́ ìbínú àti ìrunú mi, wọn yóò mọ̀ ìgbẹ̀san mi Olúwa Olódùmarè .’ "

Àsọtẹ́lẹ̀ òdì Filistia

15 25.15-17: Isa 14.29-31; Jr 47; Am 1.6-8; Sf 2.4-7; Sk 9.5-7. "Báyìí ni Olúwa Olódùmarè : Nítorí àwọn ará Filistini hùwà ̀san wọ́n gbẹ̀san pẹ̀odì ọkàn wọn, àti pẹ̀ìkórìíra gbangba àtijọ́ wíwá ̀láti pa Juda run, 16 nítorí náà báyìí Olúwa Olódùmarè , "Èmi ti ṣetán láti na ọwọ́ mi jáde àwọn ará Filistini, èmi yóò àwọn ará Kereti kúrò, èmi yóò pa àwọn ó etí kún run. 17 Èmi yóò gbẹ̀san ńlá lára wọn nípa ìbáwí gbígbóná; wọn yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa. Nígbà èmi yóò gba ̀san lára wọn." ’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também