Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 22

Àwọn ẹsẹ̀ Jerusalẹmu

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ :

2 "Ọmọ ènìyàn ǹjẹ́ ìwọ yóò ha ṣe ìdájọ́ rẹ̀? Ǹjẹ́ ìwọ ha ṣe ìdájọ́ ìlú atàjẹ̀sílẹ̀? bẹ́̀ dojúkọ wọn pẹ̀gbogbo ìwà ìríra wọn. 3 ó , Èyí yìí ohun Olúwa Olódùmarè : Ìwọ ìlú ńlá ó ìparun sórí ara rẹ nípa títàjẹ̀sílẹ̀ àárín rẹ, ó ba ara rẹ̀ jẹ́ nípa ṣíṣe àwọn ère. 4 Ìwọ ti jẹ̀bi nítorí ̀jẹ̀ ìwọ ti ta sílẹ̀, àti àwọn ère ó ṣe ́ jẹ́. Ìwọ ọjọ́ rẹ súnmọ́ tòsí, ìparí àwọn ọdún rẹ ti . Nítorí náà èmi yóò fi ṣe ohun ̀gàn lójú àwọn orílẹ̀-èdè àti ohun ̀sín lójú gbogbo ìlú. 5 Àwọn ó tòsí àti àwọn ó jìnnà , yóò fi ṣe ẹlẹ́, ìwọ ìlú ẹlẹ́gàn, ó kún fún làálàá.

6 " Wo ̀kọ̀̀kan nínú àwọn ọmọbìnrin ọba Israẹli ó nínú yín ti ń lo agbára rẹ̀ láti tàjẹ̀ sílẹ̀. 7 Nínú rẹ wọn ti hùwà baba àti ìyá pẹ̀ìfojú tínrín; nínú rẹ wọn ti ni àwọn àlejò lára, wọn hùwàkiwà aláìní baba àti opó. 8 Ìwọ kọ àwọn ohun mímọ́ mi sílẹ̀, ìwọ ti lo ọjọ́ ìsinmi mi ìlòkulò. 9 Nínú rẹ ni àwọn ayannijẹ ènìyàn pinnu láti tàjẹ̀ sílẹ̀; nínú rẹ àwọn ó ń jẹun orí òkè ojúbọ òrìṣà, wọn hùwà ìfẹ́kúfẹ̀́. 10 Nínú rẹ àwọn ti bu ọlá fún àwọn àkéte baba wọn; nínú rẹ ni àwọn o ń àwọn obìnrin nígbà wọ́n ń ṣe àkókò lọ́wọ́, àsìkò a ka wọn aláìmọ́. 11 Nínú rẹ ọkùnrin kan ti ̀ṣẹ̀ ìríra pẹ̀aya aládùúgbò rẹ̀, òmíràn ìyàwó ọmọ rẹ̀ jẹ́, òmíràn arábìnrin rẹ̀ lòpọ̀ èyí í ṣe ọbàkan rẹ̀. 12 22.12: Ek 23.8; De 16.19; Ek 22.25; Le 25.36,37; De 23.19.Nínú rẹ àwọn ènìyàn gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ láti tàjẹ̀ sílẹ̀; ìwọ gba èlé ìlọ́po láti aláìṣòótọ́ jèrè láti ara aládùúgbò rẹ nípa ìrẹ́jẹ. Ìwọ ti gbàgbé èmi; ni Olúwa Olódùmarè .

13 " Èmi yóò kúkú pàtẹ́wọ́ lórí èrè àìmọ̀ ìwọ ti jẹ, àti lórí ̀jẹ̀ ìwọ ti ta sílẹ̀ àárín yín. 14 Ọkàn rẹ le gbà á, tàbí ọwọ́ rẹ le, ọjọ́ èmi yóò ṣé? Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀, Èmi yóò ṣe é. 15 Èmi yóò yin àárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò fọ́n àwọn ìlú; èmi yóò fi òpin àìmọ́ rẹ. 16 Nígbà a ó ́ jẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè, ìwọ yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa.’ "

17 Nígbà náà ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 18 "Ọmọ ènìyàn, ilé Israẹli ti di ìdàrọ́ mi; gbogbo wọn jẹ́ bàbà, idẹ, irin àti òjé ti a fi sínú iná ìléru. Wọn jẹ́ ìdàrọ́ ti fàdákà. 19 Nítorí náà èyí yìí ni ohun ti Olúwa Olódùmarè : Nítorí ìwọ ti di ìdàrọ́, èmi yóò yín jọ Jerusalẹmu. 20 Gẹ́gẹ́ ènìyàn ṣe ń fàdákà, bàbà, irin, òjé àti idẹ jọ sínú iná ìléru láti fi iná yọ́ , bẹ́̀ ni èmi yóò jọ ìbínú àti ìrunú mi, èmi yóò fi àárín ìlú, èmi yóò yọ́ . Níbẹ̀ ìwọ yóò ti yọ́. 21 Èmi yóò yín jọ, èmi o fín iná ìbínú mi si yin lára, o si di yíyọ́ láàrín rẹ̀. 22 a ti ń yọ́ fàdákà nínú iná ìléru bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ìwọ yóò ṣe yọ́ nínú rẹ̀, ìwọ yóò mọ̀ , Èmi Olúwa ti ìbínú mi sórí rẹ.’ "

23 Lẹ́̀kan i ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ , 24 "Ọmọ ènìyàn, sọ fún ilẹ̀ náà, Ìwọ ilẹ̀ gbá mọ́, ti rọ òjò tàbí ìrì àkókò ìbínú.25 Ìdìtẹ̀ láàrín àwọn ọmọ-aládé inú rẹ̀, dàbí bíbú kìnnìún ń ẹran ya, wọ́n ń ba àwọn ènìyàn jẹ́, wọ́n ń ìṣúra àti àwọn ohun iyebíye wọ́n ń sọ púpọ̀ di opó nínú rẹ̀. 26 Àwọn àlùfáà rẹ̀ ti òfin mi, wọn si ti sọ ohun mímọ́ mi di àìlọ́wọ̀: wọn fi ìyàtọ̀ sáàrín ohun mímọ́ àti àìlọ́wọ̀, bẹ́̀ ni wọn fi ìyàtọ̀ hàn láàrín ohun àìmọ́, àti mímọ́, wọn ti fi ojú wọn pamọ́ kúrò ọjọ́ ìsinmi mi, ẹni àìlọ́wọ̀ láàrín wọn. 27 Àwọn ọmọ-aládé àárín rẹ̀ dàbí ìkookò ti ń ṣọdẹ, láti tàjẹ̀ sílẹ̀, láti pa ọkàn run, láti jèrè àìṣòótọ́. 28 Àti àwọn wòlíì rẹ́ ti ṣẹ̀tàn wọn, wọn ń ìran asán, wọn ń fọ àfọ̀ṣẹ èké wọn, , Báyìí Olúwa Olódùmarè ,nígbà ó ṣépè Olúwa sọ̀rọ̀. 29 Àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, lo ìwà ìninilára, wọn olè, wọn ni àwọn tálákà àti aláìní lára; nítòótọ́, wọn àlejò lára láìnídìí. ṣí ìdájọ́ òdodo.

30 "Èmi si ẹnìkan láàrín wọn, ìbá tún odi náà mọ́, ìbá dúró ibi ó ya náà níwájú mi fún ilẹ̀ náà, èmi à parun: ṣùgbọ́n èmi ẹnìkan. 31 Nítorí náà ni mo ṣe da ìbínú mi wọn lórí, mo ti fi iná ìbínú mi run wọn, mo si ti fi ̀wọn gbẹ̀san lórí ara wọn, Olúwa Olódùmarè ."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também