Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 44

Àwọn ọmọ ọba, àwọn Lefi àti àwọn àlùfáà

1 Lẹ́yìn náà ni ọkùnrin náà mi padà lọ ibi mímọ́, èyí ó kọjú ìhà ìlà-oòrùn, ó títì. 2 Olúwa sọ fún mi, "Ẹnu-ọ̀yìí ni ó títì. A gbọdọ̀ ṣí i sílẹ̀; ẹni o gbọdọ̀ gba ibẹ̀ wọlé. Ó gbọdọ̀ títì nítorí Olúwa Ọlọ́run Israẹli gbà ibẹ̀ wọlé. 3 Ọmọ-aládé fúnra rẹ̀ o jókòó ẹnu-ọ̀náà o jẹun níwájú Olúwa. Ó gbọdọ̀ gba ̀ìloro ẹnu-ọ̀wọlé ó gba ibẹ̀ jáde."

4 44.4: If 15.8. Lẹ́yìn náà, ọkùnrin náà mi gba ẹnu-ọ̀àríwá lọ iwájú ilé Ọlọ́run. Mo ó mo ògo Olúwa ó kún inú ilé Olúwa, mo dojúkọ ilẹ̀.

5 Olúwa sọ fún , "Ọmọ ènìyàn, dáradára, fetísílẹ̀ dáradára o fiyèsí ohun gbogbo mo sọ fún nípa òfin lórí ilé Olúwa náà. Fiyèsí ẹnu-ọ̀ilé Ọlọ́run náà àti gbogbo àbájáde ibi mímọ́. 6 Sọ fún ọlọ̀tẹ̀ ilé Israẹli , Èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè : Ìwà ìríra rẹ gẹ́́, ìwọ ilé Israẹli! 7 àfikún pẹ̀gbogbo àwọn ìwà ìríra rẹ ó , ìwọ àwọn àjèjì aláìkọlà àyà àti ara inú ibi mímọ́ mi, lílo ilé mi ìlòkulò nígbà ìwọ fi oúnjẹ fún mi, ̀àti ̀jẹ̀, ìwọ ba májẹ̀mi jẹ́. 8 Dípò ìwọ pa òfin mi mọ́, ìwọ fi àwọn mìíràn ibi mímọ́ mi. 9 Èyí yìí Olúwa Olódùmarè : Àjèjì aláìkọlà àyà àti ara gbọdọ̀ wọ ibi mímọ́ mi, àti pẹ̀àwọn àjèjì ń gbé àárín àwọn ọmọ Israẹli.

10 " Àwọn Lefi wọn rìn jìnnà kúrò lọ́dọ̀ mi nígbà àwọn ọmọ Israẹli ṣìnà, ti wọ́n ṣáko kúrò lọ́dọ̀ mi láti tọ àwọn ère wọn lẹ́yìn gbọdọ̀ jèrè ̀ṣẹ̀ wọn. 11 Wọn le sìn mi ibi mímọ́ mi, wọn ṣe ìtọ́àwọn ẹnu-ọ̀ilé Ọlọ́run, wọn ṣe ìránṣẹ́ nínú rẹ̀; wọn le pa ẹbọ sísun, ki wọn ẹbọ fún àwọn ènìyàn, wọn dúró níwájú àwọn ènìyàn, wọ́n ṣe ìránṣẹ́ fún wọn. 12 Ṣùgbọ́n nítorí wọn ṣe ìránṣẹ́ fún wọn níwájú àwọn ère wọn, wọn mu ilé Israẹli ṣubú sínú ̀ṣẹ̀, nítorí náà, Èmi búra nípa nína ọwọ́ sókè , wọn gbọdọ̀ jèrè ̀ṣẹ̀ wọn, Olúwa Olódùmarè . 13 Wọn gbọdọ̀ súnmọ́ ̀dọ̀ mi láti ṣe ìránṣẹ́ fún mi, gẹ́gẹ́ àlùfáà tàbí súnmọ́ nǹkan kan nínú àwọn ohun mímọ́ mi tàbí ẹbọ mi mímọ́ jùlọ; wọn gbọdọ̀ gba ìtìjú ìwà ìríra wọn. 14 Síbẹ̀ èmi yóò mu wọn ìtọ́ilé Ọlọ́run àti gbogbo iṣẹ́ a gbọdọ̀ ṣe níbẹ̀.

15 " Ṣùgbọ́n àwọn àlùfáà, ó jẹ́ Lefi àti àwọn ìran Sadoku fi tọkàntọkàn ṣe iṣẹ́ ibi mímọ́ mi nígbà àwọn Israẹli ṣáko lọ kúrò lọ́dọ̀ mi, wọn gbọdọ̀ súnmọ́ iwájú láti ṣe ìránṣẹ́ iwájú mi, láti ẹbọ ̀àti ̀jẹ̀, ni Olúwa Olódùmarè . 16 Àwọn nìkan ni ó gbọdọ̀ wọ ibi mímọ́ mi; àwọn nìkan o gbọdọ̀ súnmọ́ tábìlì mi láti ṣe ìránṣẹ́ ni iwájú mi, ki wọn ṣe iṣẹ́ ìsìn mi.

17 " Nígbà ti wọ́n wọ àwọn ẹnu-ọ̀àgbàlá ti inú, wọn yóò wọ ̀̀gbọ̀, wọn gbọdọ̀ wọ aṣọ onírun nígbà wọ́n ń ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ àwọn ẹnu-ọ̀àgbàlá ti inú tàbí ni inú ilé Ọlọ́run. 18 Wọ́n yóò fìlà ̀gbọ̀ orí wọn àti ṣòkòtò ̀gbọ̀ ìdí wọn. Wọn gbọdọ̀ wọ ohunkóhun yóò wọn làágùn. 19 Nígbà wọ́n lọ àgbàlá òde níbi àwọn ènìyàn , wọn gbọdọ̀ bọ́ ̀wọ́n fi ń ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́, ki wọn fi wọn sílẹ̀ àwọn yàrá mímọ́ náà, wọn ó wọ ̀mìíràn, wọn yóò fi ̀wọn sọ àwọn ènìyàn di mímọ́.

20 " Wọn gbọdọ̀ irun, wọn gbọdọ̀ jẹ́ irun wọn gùn, ṣùgbọ́n wọn gbọdọ̀ jẹ́ irun orí wọn gígẹ̀. 21 Àlùfáà kankan gbọdọ̀ mu ọtí nígbà ó wọ àgbàlá inú. 22 Wọn ko gbọdọ̀ fẹ́ opó ni ìyàwó, wọn gbọdọ̀ kọ ìyàwó wọn sílẹ̀, wọ́n fẹ́ àwọn ọmọbìnrin ti i mọ ọkùnrin , ó jẹ́ ìran àwọn ọmọ Israẹli, tàbí wọn fẹ́ àwọn opó àlùfáà. 23 Wọn yóò fi ìyàtọ̀ ó láàrín mímọ́ àti àìmọ́ kọ́ àwọn ènìyàn mi, wọn yóò fihàn wọ́n bi wọn yóò ṣe aláìmọ́ mọ̀ yàtọ̀ mímọ́.

24 " Nínú èyíkéyìí èdè-àìyedè, àwọn àlùfáà yóò dúró gẹ́gẹ́ onídàájọ́ gẹ́gẹ́ òfin mi. Wọ́n láti pa àwọn òfin àti àṣẹ mi mọ́ gbogbo àjọ̀dún a yàn, wọn gbọdọ̀ ya ọjọ́ ìsinmi mi mímọ́.

25 " Àlùfáà gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́ nípa sísún mọ́ òkú ènìyàn; ṣùgbọ́n ti òkú ènìyàn yẹn jẹ́ baba tàbí ìyá rẹ̀, àbúrò rẹ̀ ọkùnrin tàbí àbúrò rẹ̀ obìnrin ti i ti lọ́kọ, nígbà náà o le sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́. 26 Lẹ́yìn ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀, ki òun ó dúró fún ọjọ́ méje. 27 ọjọ́ ti yóò wọ àgbàlá ti inú ni ibi mímọ́ láti ṣe ìránṣẹ́ ibi mímọ́, ni òun ó ọrẹ ẹbọ ̀ṣẹ̀ ni Olúwa Olódùmarè .

28 " Èmi ni yóò jẹ́ ogún kan ṣoṣo àwọn àlùfáà yóò . yóò fún wọn ni ìpín kankan Israẹli, Èmi ni yóò jẹ́ ìní wọn. 29 Wọn yóò jẹ ọrẹ ẹbọ jíjẹ, ọrẹ ẹbọ ̀ṣẹ̀ àti ọrẹ ẹbọ ìrékọjá; gbogbo ohun a sọ́tọ̀ fún Olúwa ni Israẹli ni yóò jẹ́ tiwọn. 30 Èyí ó dára jùlọ nínú gbogbo àkọ́so èso àti ọrẹ yín yóò jẹ́ ti àwọn àlùfáà. ó fi àkọ́ìyẹ̀fun yín fún wọn ìbùkún lórí gbogbo ilé yín. 31 Àwọn àlùfáà yóò jẹ́ ohunkóhun i ẹyẹ tàbí ẹranko, ó ti fúnra rẹ̀ tàbí èyí ti ẹranko ńlá fàya.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também