Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 12

Àpẹẹrẹ àwọn ìgbèkùn

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 12.2: Mk 8.18."Ọmọ ènìyàn, ìwọ ń gbé àárín ọlọ̀tẹ̀ ènìyàn. Wọ́n lójú láti fi ríran, ṣùgbọ́n wọn ríran, bẹ́̀ ni wọ́n létí láti fi gbọ́rọ̀ ṣùgbọ́n wọn gbọ́rọ̀, torí ọlọ̀tẹ̀ ènìyàn ni wọ́n.

3 "Nítorí náà, ọmọ ènìyàn, palẹ̀ ẹrù rẹ mọ́ láti lọ ìgbèkùn, ̀sán gangan ojú wọn, kúrò láti ibi ìwọ lọ ibòmíràn. Bóyá wọ́n , wọn yóò ronú tilẹ̀ jẹ́ ọlọ̀tẹ̀ ilé ni wọ́n. 4 Di ẹrù ìgbèkùn rẹ lójú wọn ̀sán án gangan, nígbà ó di alẹ́, ojú wọn, máa lọ ìgbèkùn gẹ́gẹ́ àwọn ó lọ ìgbèkùn ṣe máa ń ṣe. 5 ògiri lu ojú wọn, ìwọ gba ibẹ̀ ẹrù rẹ jáde. 6 Gbé ẹrù rẹ èjìká ojú wọn, bo ojú rẹ, ìwọ ba à ilẹ̀, ru ẹrù rẹ lọ alẹ́ nítorí mo fi ́ ṣe àmì fún ilé Israẹli."

7 Mo ṣe gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún mi. Mo ẹrù mi jáde ̀sán án láti lọ fun ìgbèkùn. Nígbà di ìrọ̀lẹ́, mo ògiri lu pẹ̀ọwọ́ mi. Mo gbe ẹrù mi èjìká nínú òkùnkùn ojú wọn.

8 òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 9 "Ọmọ ènìyàn, ǹjẹ́ ọlọ̀tẹ̀ ilé Israẹli tilẹ̀ bi ́ , ni ohun o ń ṣe túmọ̀ ?

10 "Sọ fún wọn , Báyìí ni Olúwa Olódùmarè , ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ yìí kan àwọn ọmọ-aládé Jerusalẹmu àti gbogbo ilé Israẹli ó àárín rẹ. 11 Sọ fún wọn , Èmi jẹ́ àmì fún yín.

"Gẹ́gẹ́ mo ti ṣe, bẹ́̀ ni a ó ṣe wọn. Wọn ó lọ ìgbèkùn. Gẹ́gẹ́ ẹni ti a ìgbèkùn.

12 "Ọmọ-aládé ó àárín wọn yóò di ẹrù rẹ̀ èjìká alẹ́ yóò jáde lọ, òun náà yóò da ògiri lu ó le gba ibẹ̀ jáde. Yóò bo ojú rẹ̀ ó ba à ilẹ̀. 13 Èmi yóò ta àwọ̀n mi e lórí, yóò sínú okùn, Èmi yóò lọ Babeli, ilẹ̀ Kaldea, ṣùgbọ́n fojúrí ilẹ̀ náà ibẹ̀ ni yóò . 14 Gbogbo àwọn i láti ràn án lọ́wọ́ ̀ìtẹ̀lẹ̀ àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ ni Èmi yóò túká afẹ́fẹ́, èmi yóò tún fi idà wọn kiri.

15 "Wọn yóò mọ̀ èmi ni Olúwa nígbà mo wọn àárín àwọn orílẹ̀-èdè, mo fọ́n wọn ilẹ̀ káàkiri. 16 Ṣùgbọ́n èmi yóò ṣẹ́ díẹ̀ lára wọn, ọwọ́ idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn, wọn le jẹ́wọ́ gbogbo ìṣe ìríra wọn àárín àwọn orílẹ̀-èdè yìí. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa."

17 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 18 "Ọmọ ènìyàn, jẹ oúnjẹ rẹ pẹ̀ìwárìrì, mu omi rẹ pẹ̀ìwárìrì àti àìbalẹ̀ àyà. 19 Sọ fún àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà , Báyìí ni Olúwa Olódùmarè fún àwọn olùgbé Jerusalẹmu àti ilẹ̀ Israẹli , pẹ̀àìbalẹ̀ àyà ni wọn yóò máa jẹun wọn, wọn yóò mu omi pẹ̀àìnírètí, ilẹ̀ wọn di ahoro torí ìwà ipá àwọn ń gbé ibẹ̀. 20 Ìlú jẹ́ ibùgbé ènìyàn tẹ́lẹ̀ yóò di òfo, ilẹ̀ náà yóò di ahoro. ̀yin yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa.’ "

21 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 22 "Ọmọ ènìyàn, irú òwe wo ni pa nílẹ̀ Israẹli : A fa ọjọ́ gùn, gbogbo ìran di asán? 23 Nítorí náà fún wọn , Báyìí ni Olúwa Olódùmarè , Èmi yóò fi òpin òwe yìí, wọn ipa mọ́ Israẹli.Sọ fún wọn, Ọjọ́ náà súnmọ́ tòsí nígbà gbogbo ìran àti ìsọtẹ́lẹ̀ yóò ìmúṣẹ. 24 Nítorí ìran asán tàbí àfọ̀ṣẹ ó ń pọ́n ni mọ́ àárín ilé Israẹli. 25 Ṣùgbọ́n, Èmi Olúwa yóò sọ̀rọ̀, ̀rọ̀ mo sọ yóò ṣẹ láì falẹ̀. Báyìí ni Olúwa Olódùmarè , àsìkò yín, ̀yin ọlọ̀tẹ̀ ilé ni Èmi yóò ̀rọ̀ yówù mo sọ ṣẹ.’ "

26 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 27 "Ọmọ ènìyàn, ilé Israẹli ń , Ìran ọjọ́ pípẹ́ ni ìwọ , ìwọ sọtẹ́lẹ̀ nípa àsìkò jìnnà réré.

28 "Nítorí náà sọ fún wọn, Báyìí ni Olúwa Olódùmarè , ̀kan nínú ̀rọ̀ mi yóò sún síwájú mọ́; ṣùgbọ́n ̀rọ̀ mo sọ yóò ṣẹ.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também