Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 40

Agbègbè tẹmpili tuntun

1 40.1–43.17: 1Ọb 6–7; 2Ki 3–4. ọdún kẹẹdọ́gbọ̀n a ti ni oko ẹrú wa, ìbẹ̀rẹ̀ ọdún, ni oṣù kẹwàá ọdún kẹrìnlá lẹ́yìn ìṣubú ìlú ńlá náà ọjọ́ náà gan an ọwọ́ Olúwa ń bẹ̀ lára mi, òun mi lọ síbẹ̀. 2 40.2: If 21.10.Nínú ìran Ọlọ́run, ó lọ ilẹ̀ Israẹli, ó gbé mi lọ orí òkè gíga fíofío. ̀gbẹ́ gúúsù ̀pọ̀ ilé níbẹ̀ dàbí ìlú ńlá. 3 40.3,5: If 21.15.Ó mi lọ síbẹ̀, mo ọkùnrin kan ìrírí rẹ̀ dàbí ìrí baba; ó dúró ni ẹnu-ọ̀pẹ̀okùn aṣọ ̀gbọ̀ funfun àti ̀ìwọnlẹ̀ ọwọ́ rẹ̀. 4 Ọkùnrin náà sọ fún mi , "Ọmọ ènìyàn, pẹ̀ojú rẹ o gbọ́ pẹ̀etí rẹ, ó fi ara balẹ̀ gbogbo ohun mo máa fihàn , nítorí ìdí nìyí a fi síyìn-ín. Sọ gbogbo ohun ó fún ilé Israẹli."

Ibi àbájáde apá ilà oòrùn àgbàlá ojúde

5 Mo ògiri ó agbègbè ibi mọ̀ po. Gígùn ̀ìwọnlẹ̀ ó ọwọ́ ọkùnrin náà jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́, ̀kọ̀̀kan jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan àti ìlàsí mẹ́rin ẹsẹ̀ bàtà. Ó wọn ògiri náà; ó jẹ́ ìwọ̀nyí ̀náà ni nínípọn, ó jẹ́ ̀kan gíga.

6 Lẹ́yìn náà ni ó lọ ẹnu-ọ̀òde ó kọjú ìlà-oòrùn. Ó gun àtẹ̀gùn rẹ̀, o wọn ìloro ẹnu-ọ̀ilé; ó jẹ́ ̀kan jíjìn. 7 Yàrá kéékèèké jẹ ̀kan ni gígùn àti ̀kan ibú, ìgbéró ògiri àárín yàrá kéékèèké náà jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún ni nínípọn. Ìloro ẹnu-ọ̀náà ó kángun àtẹ̀wọ ẹnu-ọ̀náà kọjú tẹmpili jẹ́ ̀kan jíjìn.

8 Lẹ́yìn náà, ó wọ̀n ògiri àbáwọlé ẹnu-ọ̀: 9 Ó jẹ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́jọ jíjìn àtẹ́rígbà rẹ̀ jẹ ìgbọ̀nwọ́ méjì nínípọn. Ògiri àbáwọlé ẹnu-ọ̀kọjú tẹmpili.

10 ẹnu-ọ̀ìlà-oòrùn ni àwọn yàrá kéékèèké mẹ́ta ̀gbẹ́ kọ̀̀kan: mẹ́tẹ̀̀ta kọ̀ ara wọn, ojú ìgbéró ògiri ni ̀gbẹ́ kọ̀̀kan jẹ́ bákan náà wíwọ̀n. 11 Lẹ́yìn náà ó wọn ìbú à wọ ẹnu-ọ̀náà; ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́wàá, gígùn rẹ̀ jẹ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́tàlá. 12 iwájú ̀kọ̀̀kan yàrá kéékèèké kọ̀̀kan ògiri gíga rẹ jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan , ̀gbẹ́ mẹ́rẹ̀̀rin àwọn yàrá kéékèèké jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́. 13 Lẹ́yìn náà, ó wọn ẹnu-ọ̀láti òkè ̀yìn ògiri yàrá kéékèèké kan títí òkè ìdojúkọ ̀kan; jíjìn ara wọn jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́̀́dọ́gbọ̀n láti odi kan ó ṣí sílẹ̀ ìdojúkọ ̀kan. 14 Ó ṣe àtẹ́rígbà ọlọ́gọ́ta ìgbọ̀nwọ́, àní títí àtẹ́rígbà ògiri àgbàlá, ẹnu-ọ̀. 15 Láti iwájú ẹnu-ọ̀àbáwọlé títí ìparí yàrá kéékèèké náà àti àwọn ìgbéró ògiri nínú ẹnu-ọ̀a gbé jẹ́ àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́. 16 Ni a tẹ nínú yíká; àwọn mẹ́tẹ̀̀ta náà fèrèsé tóóró ó wọ inú yíká. Àwọn ògiri wọn inú ni a fi pákó tẹ yíká láti ilẹ̀ òkè fèrèsé àti láti fèrèsé òrùlé.

Àgbàlá ojúde

17 Lẹ́yìn náà ó mi lọ ojú òde àgbàlá. Níbẹ̀ mo yàrá díẹ̀ àti pèpéle a kọ́ àgbàlá ; ọgbọ̀n yàrá lẹ́gbẹ̀ pèpéle náà. 18 O ṣe ààlà ̀gbẹ́ àwọn ẹnu-ọ̀, ìbú rẹ̀ jẹ́ bákan náà pẹ̀gígùn rẹ̀: èyí jẹ́ pèpéle ìsàlẹ̀. 19 Lẹ́yìn náà, o wọn jíjìnnà rẹ̀ láti inú ìsàlẹ̀ ẹnu-ọ̀títí àgbàlá inú; ó jẹ́ ọgọ́rùn-ún ìgbọ̀nwọ́ ni ìhà ìlà-oòrùn àti àríwá.

Ẹnu ọnà àríwá

20 Lẹ́yìn náà, ó wọn gígùn àti ibú ẹnu-ọ̀ó dojúkọ àríwá, à wọ àgbàlá. 21 Àwọn yàrá kéékèèké rẹ̀ mẹ́ta ni ̀gbẹ́ kọ̀̀kan ìgbéró ògiri rẹ̀ àti àbáwọlé ẹnu-ọ̀jẹ́ bákan náà ni wíwọ̀n gẹ́gẹ́ àwọn ẹnu-ọ̀àkọ́kọ́. Ó jẹ́ àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́ ni gígùn, ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́̀́dọ́gbọ̀n ni ìbú. 22 Ojú ihò rẹ̀, àbáwọlé ẹnu-ọ̀rẹ̀ àti igi ̀pẹ í ṣe ̀ṣọ́ rẹ̀ ni wọn kàn gẹ́gẹ́ àwọn ẹnu-ọ̀ó dojúkọ ìlà-oòrùn. Àtẹ̀gùn méje ó ibẹ̀, pẹ̀àbáwọlé ẹnu-ọ̀òdìkejì wọn. 23 Ẹnu-ọ̀kan àgbàlá ti inú ni ìdojúkọ ẹnu-ọ̀àríwá, gẹ́gẹ́ o ṣe ìlà-oòrùn. Ó wọ́n láti ẹnu-ọ̀ìdojúkọ ̀kan; ó jẹ́ ọgọ́rùn-ún ìgbọ̀nwọ́.

Àbájáde ìhà gúúsù

24 Lẹ́yìn náà, o mi lọ ìhà gúúsù, mo ẹnu-ọ̀ó dojúkọ gúúsù. Ó wọn àtẹ́rígbà àti ògiri àbáwọlé ẹnu-ọ̀, wọ́n jẹ́ bákan náà ti àwọn o . 25 Ẹnu-ọ̀àti àbáwọlé ẹnu-ọ̀ni ojú ihò tóóró po, gẹ́gẹ́ ojú ihò ti àwọn tókù. Ó jẹ́ àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́ gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ mẹ́̀́dọ́gbọ̀n ìbú. 26 Àtẹ̀gùn méje ń bẹ láti gun òkè rẹ̀, àti àwọn ìloro rẹ̀ ń bẹ níwájú wọn; Ó igi ̀pẹ a fi ṣe ̀ṣọ́ rẹ̀ ni ojú ìgbéró ògiri ̀gbẹ́ kọ̀̀kan. 27 Àgbàlá ti inú náà ẹnu-ọ̀yìí ẹnu-ọ̀ìta ni ìhà gúúsù; o jẹ́ ọgọ́rùn-ún ìgbọ̀nwọ́.

Àbáwọlé si àgbàlá ti inú

28 Lẹ́yìn náà, o mi lọ àgbàlá ti inú láti ẹnu-ọ̀gúúsù, ó ìwọ̀n kan náà ẹnu-ọ̀gúúsù; ó ìwọ̀n kan náà pẹ̀àwọn ó . 29 Àwọn yàrá kéékèèké rẹ̀, àwọn ìgbéró ògiri rẹ̀ àti àbáwọlé ẹnu-ọ̀jẹ́ bákan náà pẹ̀àwọn ó . Ẹnu-ọ̀náà àti àbáwọlé ẹnu-ọ̀rẹ̀ ihò ̀gbẹ́ rẹ̀ gbogbo. 30 (Àwọn àbáwọlé ẹnu-ọ̀ó àgbàlá po jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́̀́dọ́gbọ̀n ni ìbú àti ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún ni jíjìn). 31 Àtẹ̀wọ ẹnu-ọ̀rẹ̀ ó dojúkọ ògiri àgbàlá ìta, igi ̀pẹ ṣe ̀ṣọ́ àwọn àtẹ́rígbà rẹ̀, àtẹ̀gùn mẹ́jọ ó lọ òkè i.

32 Lẹ́yìn náà, ó mi lọ àgbàlá inú ni ìhà ìlà-oòrùn, ó wọn ẹnu-ọ̀; ó ìwọ̀n kan náà pẹ̀àwọn ó . 33 Àwọn yàrá kéékèèké rẹ̀, ìgbéró ògiri rẹ̀ àti àbáwọlé ẹnu-ọ̀rẹ̀ ìwọ̀n kan náà pẹ̀àwọn ó . Ẹnu-ọ̀náà àti àbáwọlé ẹnu-ọ̀ni ihò po. Ó jẹ́ àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́ ni ìbú. 34 Àbáwọlé ẹnu-ọ̀rẹ̀ dojúkọ ògiri àgbàlá ìta; àwọn igi ̀pẹ ṣe ̀ṣọ́ àtẹ́rígbà ̀gbẹ́ méjèèjì, àtẹ̀gùn mẹ́jọ lọ sókè rẹ̀.

35 Gẹ́gẹ́ àwọn yàrá kéékèèké rẹ̀ ṣe . Àwọn ìgbéró ògiri rẹ̀ àti àbáwọlé ẹnu-ọ̀, ó àwọn ihò i po. O jẹ́ àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́ gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ mẹ́̀́dọ́gbọ̀n ìbú. 36 Àwọn yàrá ̀ṣọ́ rẹ̀ àwọn ògiri òpó rẹ̀ àti ìloro rẹ̀, àti fèrèsé rẹ̀ yíká: gígùn rẹ̀ àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́, àti ìbú rẹ̀ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́̀́dọ́gbọ̀n. 37 Àbáwọlé ẹnu-ọ̀rẹ̀ dojúkọ ògiri àgbàlá ìta; àwọn igi ̀pẹ ṣe ̀ṣọ́ àwọn àtẹ́rígbà rẹ̀ ni ̀gbẹ́ méjèèjì, àtẹ̀gùn mẹ́jọ ó so mọ́ ọn lókè.

Àwọn yàrá fún ṣíṣètò ìrúbọ

38 Yàrá kan pẹ̀ìlẹ̀kùn ̀gbẹ́ ògiri àbáwọlé ẹnu-ọ̀̀kọ̀̀kan ẹnu-ọ̀inú, níbi wọn ń fọ àwọn ẹbọ sísun. 39 àbáwọlé ẹnu-ọ̀ẹnu-ọ̀ni tẹmpili méjì ̀gbẹ́ kọ̀̀kan, lórí èyí a ti ń pa ọrẹ ẹbọ sísun, ẹbọ ̀ṣẹ̀ àti ẹbọ ̀bi ̀ṣẹ̀. 40 ̀gbẹ́ ògiri ìta àtẹ̀wọ ẹnu-ọ̀ẹnu-ọ̀, ó súnmọ́ àwọn àtẹ̀gùn àbáwọlé ẹnu-ọ̀àríwá ni tẹmpili méjì , ̀gbẹ́ kejì àtẹ̀gùn tẹmpili méjì . 41 Nítorí náà, tẹmpili mẹ́rin ni ó ̀gbẹ́ kan ẹnu-ọ̀, mẹ́rin ̀gbẹ́ kejì tẹmpili, mẹ́jọ ni gbogbo rẹ̀ lórí èyí ni a ti ń pa ohun ìrúbọ. 42 Tẹmpili mẹ́rin à fi òkúta ṣe lọ́ṣọ̀́ tún fún ẹbọ sísun, ̀kọ̀̀kan jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan àti ààbọ̀ ni gígùn, ìgbọ̀nwọ́ kan àti ààbọ̀ ìbú àti ìgbọ̀nwọ́ kan ni gíga. orí rẹ̀ ni a àwọn ohun èlò fún pípa, ọrẹ ẹbọ sísun àti àwọn ìrúbọ ó . 43 Ìlọ́po méjì ohun èlò àmúga o ìwọ̀ ̀kọ̀̀kan jẹ́ ìbú ọwọ́ gígùn, ni a so mọ́ ara ògiri yíká. Àwọn tẹmpili náà wa fún ẹran ohun ìrúbọ.

Àwọn yàrá fún àwọn àlùfáà

44 Lẹ́yìn náà ó wọn àgbàlá, ó jẹ́ ọgọ́rùn-ún ìgbọ̀nwọ́ gígùn, ó jẹ́ ọgọ́rùn-ún ìgbọ̀nwọ́ ìbú. Pẹpẹ iwájú tẹmpili. 45 Ó fún mi , "Yàrá yìí, iwájú rẹ̀ níhà gúúsù, fún àwọn àlùfáà, àwọn ti n bojútó ilé náà. 46 Iyàrá ti iwájú rẹ̀ ti o níhà àríwá, fún àwọn àlùfáà, àwọn ti ń bojútó pẹpẹ náà, àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Sadoku nínú àwọn ọmọ Lefi, wọ́n ń súnmọ́ Olúwa láti ṣe ìránṣẹ́ fún un."

47 Ó wọn àgbàlá náà, ọgọ́rùn-ún ìgbọ̀nwọ́ ni gígùn, ọgọ́rùn-ún ìgbọ̀nwọ́ ni ìbú, igun mẹ́rin lọ́gbọọgba, àti pẹpẹ ti ń bẹ níwájú ilé náà.

Tẹmpili náà

48 Ó mi lọ àbáwọlé ẹnu-ọ̀tẹmpili, ó wọn àwọn àtẹ́rígbà àbáwọlé ẹnu-ọ̀; wọ́n jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún ìbú, ̀gbẹ́ méjèèjì rẹ̀. Fífẹ̀ àbáwọlé jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rìnlá, ìgbéró àwọn ògiri náà jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́ta ìbú ̀gbẹ́ ògiri méjèèjì. 49 Àtẹ̀wọ ẹnu-ọ̀jẹ́ ogún ìgbọ̀nwọ́ ìbú, àti ìgbọ̀nwọ́ méjìlá láti iwájú ̀yìn. Láti ara àtẹ̀gùn a ti ń ibẹ̀ àwọn òpó ni ̀gbẹ́ ògiri kọ̀̀kan àwọn àtẹ́rígbà náà.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também