Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 17

Ẹyẹ idì méjì àti àjàrà

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn pa àlọ́ kan, pa òwe kan fún ilé Israẹli. 3 Sọ fún wọn , Báyìí ni Olúwa Olódùmarè , idì ńlá kan apá títóbi àti ìyẹ́ gígùn kún fún àwọ̀ oríṣìíríṣìí wa si Lebanoni, ó mu ̀ka igi kedari ga jùlọ, 4 ó ̀mùnú orí ̀ka yìí kúrò, ó un lọ ilẹ̀ oníṣòwò, ó gbìn ín ìlú àwọn oníṣòwò.

5 " Ó lára irúgbìn ilẹ̀ náà, ó gbìn ín ilẹ̀ ọlọ́ràá, lẹ́gbẹ̀́ ̀pọ̀lọpọ̀ omi, ó gbìn ín igi wílóò. 6 Ó dàgbà, ó di àjàrà kúrú ṣùgbọ́n to bolẹ̀. Àwọn ̀ka rẹ̀ kọjú i, gbòǹgbò rẹ̀ dúró lábẹ́ rẹ̀, bẹ́̀ ni ó di àjàrà, ó mu ̀ka àti ewé jáde.

7 " Ṣùgbọ́n ẹyẹ idì ńlá mìíràn tún , apá títóbi pẹ̀ìyẹ́ púpọ̀. Gbòǹgbò àjàrà náà ta lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ láti orí ilẹ̀ wọn gbìn ín , ó pẹ̀ka lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ ó le fún un ni omi. 8 Orí ilẹ̀ dára lẹ́gbẹ̀́ ̀pọ̀lọpọ̀ omi ni a gbìn ín , ó à le pẹ̀ka, so èso, ó di igi àjàrà lọ́púpọ̀.’

9 "Sọ fún wọn , Ohun Olúwa Olódùmarè nìyí, yóò gbilẹ̀ ? A i gbòǹgbò rẹ̀, ki a si èso rẹ̀ kúrò ó à le rọ? Gbogbo ewé rẹ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀ yọ ni yóò rẹ̀. nígbà agbára tàbí ènìyàn púpọ̀ láti gbòǹgbò rẹ̀ tu. 10 a tilẹ̀ tún un gbìn, yóò wa gbilẹ̀ ? i rọ pátápátá nígbà ti afẹ́fẹ́ láti ìlà-oòrùn kọlù ú. Gbogbo ewé rẹ̀ yóò rẹ̀ lórí ilẹ̀ ti dàgbà?’ "

11 Nígbà náà, ni ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mi : 12 "Sọ fún ọlọ̀tẹ̀ ilé yìí, Ǹjẹ́ mọ ìtumọ̀ àwọn nǹkan wọ̀nyí?Sọ fún wọn: Ọba Babeli Jerusalẹmu, ó ọba àti àwọn ìjòyè ọmọ-aládé ibẹ̀ lọ Babeli lọ́dọ̀ rẹ̀. 13 Lẹ́yìn èyí, ó ̀kan nínú ọmọ ọba májẹ̀, ó un ìbúra, ó tún àwọn alágbára ilẹ̀ náà lọ. 14 ìjọba ilẹ̀ náà le rẹ ilẹ̀, ó gbé ara rẹ̀ sókè, ó dúró nípa pípa májẹ̀rẹ̀ mọ́. 15 Ṣùgbọ́n ọba ṣọ̀tẹ̀ i nípa ríran àwọn ikọ̀ rẹ̀ lọ Ejibiti, wọn à fún un ni ẹṣin àti àwọn ọmọ-ogun púpọ̀. Yóò ha ṣe àṣeyọrí? Ṣe ẹni ṣe irú nǹkan yìí yóò bọ́ níbẹ̀? Yóò ha dalẹ̀ tán ó bọ́ níbẹ̀ ?

16 " mo ti láààyè ni Olúwa Olódùmarè , òun yóò Babeli, ilẹ̀ ọba fi sórí oyè, ìbúra ẹni ó kẹ́gàn àti májẹ̀ẹni ó . 17 Farao pẹ̀àwọn ọmọ-ogun àti àjọ ńlá rẹ̀ ṣe ìrànwọ́ fún un lójú ogun. Nígbà wọ́n pa bùdó ogun í, wọ́n mọ odi láti pa ̀pọ̀ ènìyàn. 18 Nítorí ó kẹ́gàn ìbúra nípa dída májẹ̀, àti ó juwọ́ sílẹ̀ nínú ṣíṣe ìlérí, yóò bọ níbẹ̀ pẹ̀gbogbo àwọn nǹkan ó ṣe yìí.

19 " Nítorí náà Olúwa Olódùmarè , mo ti láààyè, Èmi yóò ̀san ̀jẹ́ mi kẹ́gàn àti májẹ̀mi wa sórí rẹ̀. 20 Èmi yóò ta àwọ̀n mi sórí rẹ̀, yóò bọ sínú okùn mi, Èmi yóò lọ Babeli láti ṣe ìdájọ́ ìwà ̀dàlẹ̀ mi. 21 Gbogbo ìgbèkùn àti ̀wọ́ ọmọ-ogun rẹ̀ ni yóò pẹ̀idà, èmi yóò fọn àwọn ìyókù sínú afẹ́fẹ́ káàkiri. Nígbà náà ni yóò mọ̀ , "Èmi Olúwa ni ó ti sọ̀rọ̀."

22 " Báyìí Olúwa Olódùmarè , Èmi fúnra mi yóò ̀kan lára ̀ka ó ga jùlọ lórí igi kedari gíga, èmi yóò gbìn ín, èmi yóò ̀mùnú ó ṣẹ̀ṣẹ̀ yọ láti òkè, èmi yóò gbìn ín sórí òkè ga lókìkí. 23 17.23: El 31.6; Mt 13.32; Mk 4.32; Lk 13.19.ibi gíga òkè Israẹli ni èmi yóò gbìn ín ; yóò pẹ̀ka, yóò so èso, yóò wa di igi kedari ó lọ́. Oríṣìíríṣìí ẹyẹ yóò fi òjìji abẹ ̀ka rẹ ṣe ibùgbé; wọn yóò ṣe ibùgbé si abẹ́ òjìji ̀ka rẹ̀. 24 Gbogbo igi inú oko yóò mọ̀ , Èmi Olúwa ni ó igi gíga walẹ̀, mo kúkúrú ga sókè, mo mu igi tútù gbẹ, mo igi gbígbẹ rúwé.

" Èmi Olúwa ni ó sọ bẹ́̀, Èmi yóò ṣe e.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também