Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 20

Abrahamu àti Abimeleki

1 Abrahamu kúrò níbẹ̀ lọ ìhà gúúsù ó ń gbé agbede-méjì Kadeṣi àti Ṣuri; ó gbé ìlú Gerari fún ìgbà díẹ̀. 2 20.2: Gẹ 12.13; 26.7.Abrahamu sọ ti Sara aya rẹ̀ níbẹ̀ , "Arábìnrin mi ni." Abimeleki ọba Gerari ránṣẹ́ Sara ààfin rẹ̀.

3 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run tọ Abimeleki ojú àlá lọ́jọ́ kan, ó fún un , "Kíyèsi, ohun o fi sàn ju òkú lọ, nítorí obìnrin ìwọ sọ́dọ̀ n , aya ẹni kan íṣe."

4 Ṣùgbọ́n Abimeleki ìbá obìnrin náà lòpọ̀, nítorí náà ó , "Olúwa ìwọ yóò run orílẹ̀-èdè aláìlẹ́bi ? 5 Ǹjẹ́ òun sọ fún mi , Arábìnrin mi ni,obìnrin náà pẹ̀sọ , Arákùnrin ni? òtítọ́ pẹ̀ọkàn mímọ́ àti ọwọ́ mímọ́, ni mo ṣe èyí."

6 Nígbà náà ni Ọlọ́run fún un nínú àlá náà , "Bẹ́̀ ni, mo mọ̀ pẹ̀òtítọ́ inú ni ìwọ ṣe èyí, èyí ni mo fi pa ́ mọ́ ń jẹ́ o ṣẹ̀ mi. Ìdí nìyí n fi jẹ́ o ìbálòpọ̀ pẹ̀obìnrin náà. 7 Nísinsin yìí, aya ọkùnrin náà padà, nítorí wòlíì ni, yóò gbàdúrà fún , ìwọ yóò . Ṣùgbọ́n ìwọ a padà, mọ̀ dájú ìwọ àti gbogbo ẹni í ṣe tìrẹ yóò ."

8 òwúrọ̀ kùtùkùtù ọjọ́ kejì, Abimeleki pe gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀. Nígbà ó sọ gbogbo ohun ó ṣẹlẹ̀ fún wọn, ̀wọ́n gidigidi. 9 Nígbà náà ni Abimeleki pe Abrahamu ó fún un , "Èwo ni èyí ìwọ ṣe wa yìí? ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ̀ ́ ìwọ fi ìdálẹ́bi ńlá orí èmi àti ìjọba mi? yẹ ìwọ hu irú ìwà yìí mi." 10 Abimeleki bi Abrahamu , "Kín ìwọ fi ṣe èyí?"

11 Abrahamu dáhùn , "Mo ṣe èyí nítorí mo nínú ara mi , ̀yin níhìn-ín, bẹ̀Ọlọ́run, , le pa nítorí aya mi. 12 Yàtọ̀ fún ìyẹn, òtítọ́ ni arábìnrin mi ni. Ọmọ baba kan ni , ó tilẹ̀ jẹ́ , a í ṣe ọmọ ìyá kan. Mo fẹ́ aya. 13 Nígbà Ọlọ́run mi rìn kiri kúrò ilé baba mi, mo fún un , Èyí ni ̀ó gbà fihàn ó fẹ́ràn mi. Gbogbo ibi a máa sọ , "Arákùnrin rẹ ni ." ’ "

14 Nígbà náà ni Abimeleki àgùntàn àti màlúù , àti ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin, ó wọn fún Abrahamu, ó Sara aya rẹ̀ padà fún un. 15 Abimeleki tún fún un , "Gbogbo ilẹ̀ nìyí níwájú rẹ, máa gbé ibikíbi o fẹ́ níbẹ̀."

16 Abimeleki fún Sara , "Mo fi ẹgbẹ̀rún (1,000) owó ẹyọ fàdákà fún arákùnrin rẹ. Èyí ni owó ìtánràn ̀ṣẹ̀ mi níwájú gbogbo ẹni ó pẹ̀rẹ àti , a láre pátápátá."

17 Nígbà náà, Abrahamu gbàdúrà Ọlọ́run, Ọlọ́run wo Abimeleki àti aya rẹ̀ àti àwọn ẹrúbìnrin rẹ̀ sàn. Wọ́n tún ń bímọ, 18 nítorí Olúwa ti gbogbo ará ilé Abimeleki nínú nítorí Sara aya Abrahamu.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também