Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 30

1 Nígbà Rakeli i pe òun bímọ, ó bẹ̀rẹ̀ ṣe ìlara Lea, arábìnrin rẹ̀, ó fún Jakọbu , "Fún mi lọ́mọ, ṣe bẹ́̀, èmi ó !"

2 Inú Jakọbu i, ó , "Èmi ha ipò Ọlọ́run, ẹni ó yàgàn ?"

3 Nígbà náà ni Rakeli , "Biliha ìránṣẹ́bìnrin mi nìyìí, a lòpọ̀, ó ba à le ọmọ fún mi, èmi si le è tipasẹ̀ rẹ̀ ọmọ."

4 Báyìí ni Rakeli fi Biliha fún Jakọbu aya, ó a lòpọ̀. 5 Biliha lóyún, ó ọmọkùnrin kan fún Jakọbu. 6 Rakeli , "Ọlọ́run ti ṣe ìdájọ́ mi; ó ti gbọ́ ohùn ̀bẹ̀ mi, ó fún mi ni ọmọkùnrin kan." Nítorí ìdí èyí ni ó ṣe pe orúkọ rẹ̀ Dani.

7 Biliha, ọmọ ̀dọ̀ Rakeli tún lóyún, ó ọmọkùnrin kejì fún Jakọbu. 8 Nígbà náà ni Rakeli , "Mo ti ̀gbọ́n mi ja ìjàkadì ńlá, èmi ti borí." Ó pe orúkọ rẹ̀ Naftali.

9 Nígbà Lea ri òun ko tún lóyún mọ́, ó fi ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ obìnrin, Silipa fún Jakọbu aya. 10 Silipa ọmọ ̀dọ̀ Lea ọmọkùnrin kan fún Jakọbu. 11 Nígbà náà ni Lea , "Orí rere ni èyí!" Ó pe orúkọ rẹ̀ Gadi.

12 Silipa ọmọ ̀dọ̀ Lea tún ọmọkùnrin kejì fún Jakọbu. 13 Nígbà náà ni Lea , "Mo ayọ̀ gidigidi! Àwọn ọmọbìnrin yóò máa pe Alábùkún fún." Ó pe orúkọ rẹ̀ Aṣeri.

14 ọjọ́ kan, àkókò ìkórè ọkà jéró, Reubeni jáde lọ oko, ó èso mándrákì, ó un tọ Lea ìyá rẹ̀ . Rakeli fún Lea , "Jọ̀wọ́ fún mi ara èso mándrákì ọmọ rẹ ."

15 Ṣùgbọ́n Lea dalóhùn , "Ọkọ mi o gbà kọ́? Ṣe ìwọ yóò tún gba èso mándrákì ọmọ mi pẹ̀?"

Rakeli dáhùn , "Ó dára, yóò sùn ́ lálẹ́ yìí nítorí èso mándrákì ọmọ rẹ."

16 Nítorí náà, nígbà Jakọbu ti oko ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà, Lea jáde lọ pàdé rẹ̀, ó , "O láti sun ̀dọ̀ mi alẹ́ yìí nítorí mo ti fi èso mándrákì ọmọ mi bẹ̀ ́ lọ́wẹ̀." Nítorí náà ni Jakọbu sùn í alẹ́ ọjọ́ náà.

17 Ọlọ́run gbọ́ ti Lea, ó lóyún, ó ọmọkùnrin karùn-ún fún Jakọbu. 18 Nígbà náà ni Lea , "Ọlọ́run ti sẹ̀san ọmọ ̀dọ̀ mi ti mo fi fún ọkọ mi fún mi," ó pe orúkọ rẹ̀ Isakari.

19 Lea tún lóyún, ó ọmọkùnrin kẹfà fún Jakọbu. 20 Nígbà náà ni Lea tún "Ọlọ́run ti fún mi ̀bùn iyebíye, nígbà yìí ni ọkọ mi yóò máa bu ọlá fún mi." Nítorí náà ni ó ṣe pe orúkọ rẹ̀ ni Sebuluni.

21 Lẹ́yìn èyí, ó ọmọbìnrin kan, ó pe orúkọ rẹ̀ Dina.

22 Nígbà náà ni Ọlọ́run rántí Rakeli, Ọlọ́run gbọ́ tirẹ̀, ó ṣí i inú. 23 Ó lóyún, ó ọmọkùnrin kan ó , "Ọlọ́run ti ̀gàn mi kúrò." 24 Ó pe orúkọ rẹ̀ ni Josẹfu, ó , "Ǹjẹ́ Olúwa ó fi ọmọkùnrin mìíràn kún un fún mi."

Agbo ẹran Jakọbu pọ̀ i

25 Lẹ́yìn Rakeli ti Josẹfu, Jakọbu fún Labani , "Jẹ́ èmi máa lọ ilẹ̀ mi mo ti . 26 àwọn ọmọ àti ìyàwó mi fún mi, àwọn ẹni mo ti torí wọn sìn ́. Ki èmi máa ̀mi lọ. O à mọ mo ti ṣiṣẹ́ sìn ́ ."

27 Ṣùgbọ́n Labani fún un , "o ṣe mo ojúrere rẹ, jọ̀wọ́ dúró, nítorí, mo ti ṣe àyẹ̀rẹ, mo i Olúwa bùkún mi nítorí rẹ. 28 Sọ ohun o fẹ́ gẹ́gẹ́ owó iṣẹ́ ̀ rẹ, èmi yóò san án."

29 Jakọbu fún un , "Ìwọ à mọ mo ti ṣiṣẹ́ sìn ́ àti ẹran ̀sìn rẹ ti pọ̀ si lábẹ́ ìtọ́mi. 30 Ìwọ̀nba díẹ̀ à ni o èmi , ó ti pọ̀ i gidigidi, Olúwa ti bùkún nínú gbogbo èyí mo ṣe. Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, nígbà wo èmi yóò pèsè fún ìdílé tèmi."

31 Ó tún béèrè , "Kín ni èmi ó fi fún ?"

Jakọbu dáhùn , "fun mi ni ohunkóhun, ṣùgbọ́n ìwọ yóò ṣe ohun mo fẹ́ sọ yìí, èmi yóò máa tọ́àwọn agbo ẹran rẹ, èmi yóò máa bọ́ wọn. 32 Jẹ́ èmi ó la agbo ẹran kọjá òní, èmi yóò gbogbo àgùntàn onílà àti èyí ó àmì, àti gbogbo àgbò dúdú pẹ̀ewúrẹ́ onílà tàbí ó àmì. Àwọn wọ̀nyí ni yóò dúró fún owó iṣẹ́ mi. 33 Òtítọ́ inú mi yóò jẹ́rìí fún mi ọjọ́ iwájú nígbà ìwọ wo owó iṣẹ́ mi ìwọ san fún mi, yóò ṣe gbogbo èyí í ṣe onílà tàbí alámì nínú ewúrẹ́ tàbí í ṣe dúdú nínú àgùntàn, o ni ̀dọ̀ mi ni o mi lọ́rùn jíjí ni mo gbé."

34 Labani dáhùn , "Mo fi ara mọ́ ọn, ṣe ìwọ ti ." 35 ọjọ́ náà gan an ni Labani gbogbo ewúrẹ́ ó àmì tàbí ilà (àti òbúkọ àti abo, ó funfun díẹ̀ lára), pẹ̀gbogbo àgùntàn dúdú, ó fi wọ́n ìtọ́àwọn ọmọ rẹ̀. 36 Ibi Labani àti Jakọbu ara wọn, ìrìn ọjọ́ mẹ́ta. Jakọbu ń tọ́agbo ẹran Labani ó .

37 Nígbà náà ni Jakọbu ̀tẹ́́rẹ́ tútù kan lára igi Poplari, àti igi almondi àti igi Pileeni. Ó èèpo kúrò ibi kọ̀̀kan lára igi náà láti fún igi náà àwọ̀ ju ẹyọ kan lọ. 38 Ó àwọn ̀wọ̀nyí ̀́kán agbada omi níbi àwọn ẹran ti i nígbà wọ́n mu omi. 39 àwọn ẹran ń gùn, níwájú àwọn ̀náà, wọn àwọn ẹran onílà àti alámì, àwọn ó tótòtó lára. 40 Nígbà náà ni ó ya àwọn abo ẹran kúrò nínú agbo ẹran Labani, ó wọ́n sọ́tọ̀ kúrò lára àgbò, ó wọn máa gùn pẹ̀àwọn àgbò Jakọbu dúdú nìkan, bẹ́̀ ni ó agbo ẹran jọ fún ara rẹ̀ láti ara agbo ẹran Labani. 41 Nígbàkígbà àwọn ẹran ó lera ń gùn, Jakọbu yóò fi àwọn ̀wọ̀nyí lélẹ̀ níwájú wọn, ibi wọn ti ń mu omi. 42 Ṣùgbọ́n ó jẹ́ wọn lera, fi àwọn ̀náà lélẹ̀. Nítorí náà, àwọn lera ń jẹ́ ti Labani, nígbà àwọn ó lera ń jẹ́ ti Jakọbu. 43 Nítorí ìdí èyí, Jakọbu di ọlọ́rọ̀ gidigidi, agbo ẹran rẹ̀ pọ̀ àti àwọn ìránṣẹ́kùnrin, ìránṣẹ́bìnrin pẹ̀ìbákasẹ àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também