Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 10

Ìran àwọn ọmọ Noa

1 Èyí ni ìran àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti, àwọn náà ọmọ lẹ́yìn ìkún omi.

Ìran Jafeti

2 Àwọn ọmọ Jafeti ni:

Gomeri, Magogu, Madai, Jafani, Tubali, Meṣeki àti Tirasi.

3 Àwọn ọmọ Gomeri ni:

Aṣkenasi, Rifati àti Togarma.

4 Àwọn ọmọ Jafani ni:

Eliṣa, Tarṣiṣi, Kittimu, àti Dodanimu. 5 (Láti ̀dọ̀ àwọn wọ̀nyí ni àwọn ń gbé agbègbè omi ti tàn agbègbè wọn, gẹ́gẹ́ ̀wọn, ìdílé wọn orílẹ̀-èdè wọn, olúkúlùkù pẹ̀èdè tirẹ̀).

Ìran Hamu

6 Àwọn ọmọ Hamu ni:

Kuṣi, Ejibiti, Puti àti Kenaani.

7 Àwọn ọmọ Kuṣi ni:

Seba, Hafila, Sabta, Raama, àti Sabteka.

Àwọn ọmọ Raama ni:

Ṣeba àti Dedani.

8 Kuṣi Nimrodu, ẹni ó di alágbára jagunjagun ayé. 9 Ó jẹ́ ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa; nítorí náà ni a ṣe ń , "Nimrodu, ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa." 10 Ìjọba rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni Babeli, Ereki, Akkadi, Kalne, gbogbo wọn ilẹ̀ Ṣinari. 11 Láti ilẹ̀ náà ni ó ti lọ Asiria, níbi ó ti tẹ ìlú Ninefe, Rehoboti àti Kala, 12 àti Resini, ó àárín Ninefe àti Kala, ó jẹ́ ìlú olókìkí.

13 Ejibiti

Ludimu, Anamimu, Lehabimu, Naftuhimu. 14 Patrusimu, Kasluhimu (láti ̀dọ̀ ẹni àwọn ará Filistini ti ) àti àwọn ará Kaftorimu.

15 Kenaani Sidoni àkọ́rẹ̀,

àti Heti. 16 Àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi, 17 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini, 18 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.

Lẹ́yìn èyí ni àwọn ̀Kenaani tànkálẹ̀. 19 Ààlà ilẹ̀ àwọn ará Kenaani Sidoni, lọ Gerari títí Gasa, lọ Sodomu, Gomorra, Adma àti Seboimu, títí Laṣa.

20 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Hamu, gẹ́gẹ́ ̀wọn, àti èdè wọn, ìpínlẹ̀ wọn àti orílẹ̀-èdè wọn.

Ìran Ṣemu

21 A àwọn ọmọ fún Ṣemu Jafeti jẹ́ ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin: Ṣemu ni baba gbogbo àwọn ọmọ Eberi.

22 Àwọn ọmọ Ṣemu ni:

Elamu, Aṣuri, Arfakṣadi, Ludi àti Aramu.

23 Àwọn ọmọ Aramu ni:

Usi, Huli, Geteri àti Meṣeki.

24 Arfakṣadi Ṣela,

Ṣela Eberi.

25 Eberi ọmọ méjì:

̀kan ń jẹ́ Pelegi, nítorí ìgbà ọjọ́ rẹ̀ ni ilẹ̀ ya; orúkọ arákùnrin rẹ̀ ni Joktani.

26 Joktani

Almodadi, Ṣelefi, Hasarmafeti, Jera. 27 Hadoramu, Usali, Dikla, 28 Obali, Abimaeli, Ṣeba. 29 Ofiri, Hafila àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.

30 Agbègbè ibi wọn ń gbé bẹ̀rẹ̀ láti Meṣa títí Sefari, àwọn ilẹ̀ kún fún òkè ìlà-oòrùn.

31 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ̀ọmọ Ṣemu gẹ́gẹ́ ìdílé wọn, èdè wọn, ilẹ̀ wọn àti orílẹ̀-èdè wọn.

32 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ̀ọmọ Noa gẹ́gẹ́ ìran wọn, orílẹ̀-èdè wọn. ipasẹ̀ wọn ni àwọn ènìyàn ti tàn ilẹ̀ ayé lẹ́yìn ìkún omi.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também