Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 24

Isaaki àti Rebeka

1 Abrahamu ti di arúgbó àkókò yìí, Olúwa ti bùkún fún un ni gbogbo ̀, 2 Abrahamu fún olórí àwọn ìránṣẹ́ ilẹ̀ rẹ̀, ó jẹ́ alábojútó ohun gbogbo ó , "Fi ọwọ́ rẹ abẹ́ itan mi. 3 Èmi yóò búra lórúkọ Olúwa Ọlọ́run ̀run àti ayé, , ìwọ yóò fẹ́ aya fún ọmọ mi nínú àwọn ọmọbìnrin ará Kenaani, láàrín àwọn ẹni èmi ń gbé. 4 Ṣùgbọ́n, ìwọ yóò lọ orílẹ̀-èdè mi, láàrín àwọn ará mi láti fẹ́ aya fún Isaaki, ọmọ mi."

5 Ìránṣẹ́ náà bi í , "Ǹjẹ́ ọmọbìnrin náà kọ̀ láti mi ilẹ̀ yìí ń kọ́? Ǹjẹ́ mo ọmọ rẹ padà lọ orílẹ̀-èdè níbi ìwọ ti ?"

6 Abrahamu fún un , "i dájú ìwọ ọmọ mi padà lọ ibẹ̀." 7 "Olúwa, Ọlọ́run ̀run ó mi jáde láti ilẹ̀ baba mi àti ilẹ̀ a mi, ó mi sọ̀rọ̀ ó búra fún mi , Irú-ọmọ rẹ ni n ó fi ilẹ̀ yìí fún,yóò rán angẹli rẹ̀ ṣáájú rẹ, ìwọ ó aya fẹ́ fún ọmọ mi láti ibẹ̀. 8 obìnrin náà fẹ́ tẹ̀, nígbà náà ni a sílẹ̀ kúrò nínú ìbúra yìí, ṣùgbọ́n pàtàkì ni ìwọ gbọdọ̀ ọmọ mi padà lọ ibẹ̀." 9 Ìránṣẹ́ náà fi ọwọ́ rẹ̀ abẹ́ itan Abrahamu olúwa rẹ̀, ó búra fún nítorí ̀rọ̀ náà.

10 Ìránṣẹ́ náà ìbákasẹ mẹ́wàá, pẹ̀onírúurú ohun dáradára láti ̀dọ̀ olúwa rẹ̀, ó dìde ó lọ Aramu-Naharaimu, ìlú Nahori, 11 ó àwọn ìbákasẹ náà kúnlẹ̀ nítòsí kànga lẹ́yìn ìlú, ó ti ń di ọwọ́ ìrọ̀lẹ́ àkókò àwọn obìnrin máa ń lọ pọn omi.

12 Ó gbàdúrà , "Olúwa, Ọlọ́run Abrahamu olúwa à mi; jẹ́ n ṣe àṣeyọrí lónìí, fi àánú hàn fún Abrahamu olúwa mi. 13 Kíyèsi i, mo dúró ̀kànga omi yìí, àwọn ọmọbìnrin ìlú yìí ń jáde pọn omi. 14 Jẹ́ ó ṣe nígbà mo fún ̀kan nínú àwọn ọmọbìnrin pe, Jọ̀wọ́ sọ ládugbó rẹ kalẹ̀, n le mu omi,ó , Mu ún, èmi ó fún àwọn ìbákasẹ rẹ náà mu pẹ̀,jẹ́ ó ṣe èyí o yàn fún ìránṣẹ́ rẹ Isaaki. Nípa èyí ni n ó fi mọ̀ o ti fi àánú hàn fún olúwa mi."

15 o di , ó parí àdúrà, Rebeka pẹ̀ìkòkò omi rẹ̀ èjìká rẹ̀. Ọmọ Betueli ni. Betueli yìí ni Milka fún Nahori arákùnrin Abrahamu. 16 Ọmọbìnrin náà rẹwà, wúńdíá ni, ì mọ ọkùnrin, ó lọ ibi ìsun omi náà, ó pọn omi sínú ìkòkò omi, ó gbé e, ó ń gòkè bọ̀ kúrò níbi omi.

17 Ìránṣẹ́ náà súré lọ pàdé rẹ̀, ó fun un , "Jọ̀wọ́ fún mi ni omi díẹ̀ nínú ìkòkò omi rẹ."

18 Òun náà dáhùn , "Mu, olúwa mi," ó yára sọ ìkòkò omi náà ka ọwọ́ rẹ̀, ó fún un mu.

19 Lẹ́yìn ó ti fún un ni omi mu tán, ó , "Èmi ó bu omi fún àwọn ìbákasẹ rẹ pẹ̀títí wọn yóò fi mu àmutẹ́rùn." 20 Ó yára da omi inú ìkòkò omi rẹ̀ sínú ìbùmu, ó sáré padà lọ ibi omi láti pọn i fún àwọn ìbákasẹ, títí ó fi pọn fún gbogbo wọn. 21 Láìsọ ̀rọ̀ kan, ìránṣẹ́ yìí ń wo ọmọbìnrin náà fínní fínní láti mọ̀ bóyá Olúwa ti ṣe ìrìnàjò òun rere tàbí bẹ́̀ kọ́.

22 Lẹ́yìn àwọn ìbákasẹ náà ti mu omi tán, ni ọkùnrin náà òrùka wúrà ààbọ̀ ìwọ̀n ṣékélì àti júfù méjì fún ọwọ́ rẹ̀, ìwọ̀n ṣékélì wúrà mẹ́wàá. 23 Lẹ́yìn náà, ó béèrè , "Ọmọ ta ni ìwọ í ṣe? Jọ̀wọ́ fún mi, ǹjẹ́ ààyè ilé baba rẹ láti wọ̀ alẹ́ yìí?"

24 Ó dáhùn , "Betueli ọmọ Milka fún Nahori ni baba mi." 25 Ó fi kún un , "Àwa koríko àti ṣakaṣaka pẹ̀, àti ààyè láti wọ̀ ."

26 Nígbà náà ni ọkùnrin náà tẹríba, ó sin Olúwa, 27 pe, "Olùbùkún ni fún Olúwa, Ọlọ́run Abrahamu olúwa mi ti jẹ́ àánú àti òtítọ́ rẹ̀ ó yẹ̀ lọ́dọ̀ olúwa mi. ti èmi Olúwa ti darí ìrìnàjò mi ilé ìbátan olúwa mi."

28 Ọmọbìnrin náà sáré, ó lọ sọ ohun gbogbo wọ̀nyí fún àwọn ará ilé ìyá rẹ̀. 29 Rebeka arákùnrin ń jẹ́ Labani; Labani sáré lọ ọkùnrin náà etí odò. 30 ó ti òrùka imú àti ̀gbà ọwọ́ arábìnrin rẹ̀ ó tún gbọ́ ohun Rebeka sọ ọkùnrin náà sọ fún òun, ó jáde lọ ọkùnrin náà, ó a, ó dúró ti ìbákasẹ wọ̀n-ọn-nì ̀ìsun omi. 31 Ó fún ọkùnrin náà , ", ìwọ ẹni ìbùkún Olúwa, èéṣe o dúró ìta níhìn-ín? Mo ti pèsè ààyè sílẹ̀ fún àti ààyè fún àwọn ìbákasẹ rẹ."

32 Ọkùnrin náà Labani lọ ilé, ó ẹrù orí ìbákasẹ rẹ̀ sílẹ̀, ó fún wọn ni koríko àti oúnjẹ. Ó bu omi fún ọkùnrin náà àti àwọn arákùnrin rẹ̀ láti wẹ ẹsẹ̀ wọn. 33 Wọ́n gbé oúnjẹ síwájú rẹ̀, ṣùgbọ́n, ó , "Èmi jẹun àyàfi mo sọ ohun mo í sọ."

Labani , "burú, sọ ́."

34 Nítorí náà, ó , "Ìránṣẹ́ Abrahamu ni èmi. 35 Olúwa ti bùkún olúwa mi gidigidi. Ó ti di ọlọ́rọ̀, Ó ti fún un àgùntàn, màlúù, àti fàdákà àti wúrà, ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin àti ìbákasẹ àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́. 36 Sara aya olúwa mi ti ọmọkùnrin kan fún un, ìgbà ogbó rẹ̀, olúwa mi ti fún ọmọ náà ohun gbogbo ó . 37 Olúwa mi ti mi búra , Ìwọ gbọdọ̀ fẹ́ aya fún ọmọ mi, láàrín àwọn ọmọbìnrin Kenaani, ilẹ̀ ibi èmi ń gbé, 38 ṣùgbọ́n lọ ìdílé baba mi láàrín àwọn ìbátan mi o fẹ́ aya fún ọmọ mi.

39 "Mo olúwa mi léèrè , Ǹjẹ́ ọmọbìnrin náà fẹ́ mi ń kọ́?’

40 "Ó dáhùn , Olúwa, níwájú ẹni èmi ń rìn yóò rán Angẹli rẹ̀ ṣáájú rẹ yóò jẹ́ o ṣe àṣeyọrí ìrìnàjò rẹ, ìwọ ó ba le fẹ́ aya fún ọmọ mi, láàrín àwọn ìbátan mi, àti láàrín àwọn ìdílé baba mi. 41 Nígbà ìwọ lọ ̀dọ̀ ìdílé baba mi (gẹ́gẹ́ mo ), nígbà náà ni ìwọ bọ́ nínú ìbúra yìí.

42 "Nígbà mo ibi ìsun omi lónìí, mo , Olúwa Ọlọ́run Abrahamu olúwa mi, ìwọ fẹ́, jọ̀wọ́ jẹ́ n ṣe àṣeyọrí lórí ohun mo yìí. 43 ó, mo dúró ̀ìsun omi yìí, ó ṣe , nígbà wúńdíá kan jáde pọn omi, èmi fún un , "Jọ̀wọ́ fún mi ìwọ̀nba omi díẹ̀ mu nínú ládugbó rẹ," 44 ó fún mi , "Mu ún, èmi yóò tún pọn omi fún àwọn ìbákasẹ rẹ pẹ̀," jẹ́ ẹni náà jẹ́ ẹni Olúwa yàn fún ọmọ Abrahamu, olúwa mi.

45 "n gbàdúrà tán nínú ọkàn mi, Rebeka jáde pẹ̀ìkòkò omi rẹ̀ èjìká rẹ̀, ó lọ ibi ìsun omi ó pọn omi. Mo fun un , Jọ̀wọ́ fún mi ni omi mu.

46 "Kíákíá ni ó sọ ìkòkò rẹ̀ kalẹ̀ láti èjìká rẹ̀, ó fún mi , Mu ún, èmi yóò tún fún àwọn ìbákasẹ rẹ mu pẹ̀.Mo mu, ó tún fún àwọn ìbákasẹ mi mu pẹ̀.

47 "Mo béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , Ọmọ ta ìwọ í ṣe?

"Ó fún mi , Ọmọbìnrin Betueli í ṣe ọmọ Nahori ni òun, Milka ni ìyá òun.

"Nígbà náà ni mo fi òrùka náà bọ imú rẹ̀, mo fi ̀gbà ọwọ́ náà si ọwọ́. 48 Èmi tẹríba, mo wólẹ̀ fún Olúwa, fi ìbùkún fún Ọlọ́run Abrahamu olúwa mi, ẹni ó mi tọ ̀títọ́ láti ọmọ ọmọ arákùnrin olúwa mi fún ọmọ rẹ̀. 49 Ǹjẹ́ nísinsin yìí ̀yin yóò fi inú rere àti òtítọ́ olúwa mi , sọ fún mi, bẹ́̀ kọ́, sọ fún mi, ń le è mọ ̀èmi yóò ."

50 Labani àti Betueli dáhùn , "Lọ́dọ̀ Olúwa ni èyí ti , nítorí náà àwa le sọ rere tàbí búburú fún . 51 Rebeka nìyí, un ó máa lọ, ó di aya ọmọ olúwa à rẹ, Olúwa ti fẹ́."

52 Nígbà ọmọ ̀dọ̀ Abrahamu gbọ́ ohun wọ́n , ó wólẹ̀ níwájú Olúwa. 53 Nígbà náà ni ó ohun èlò wúrà àti fàdákà jáde àti aṣọ, ó fi wọ́n fún Rebeka, ó fún arákùnrin Rebeka àti ìyá rẹ̀ ̀bùn olówó iyebíye pẹ̀. 54 Lẹ́yìn náà ni òun àti àwọn ọkùnrin ó a jẹ, wọ́n mu, wọn sùn níbẹ̀ òru ọjọ́ náà.

wọ́n ti dìde òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó , "rán mi padà lọ ̀dọ̀ olúwa mi."

55 Ṣùgbọ́n arákùnrin Rebeka àti ìyá rẹ̀ fèsì , "A fẹ́ Rebeka pẹ̀wa fún nǹkan ọjọ́ mẹ́wàá i, lẹ́yìn èyí, ìwọ le máa mu lọ."

56 Ṣùgbọ́n ó fún wọn , "ṣe mi dúró, Olúwa à ti ṣe ̀mi rere. rán mi lọ, èmi ó le è tọ olúwa à mi lọ."

57 Nígbà náà ni wọ́n sọ , "Jẹ́ a pe ọmọ náà gan an a bi í." 58 Wọ́n pe Rebeka wọ́n bi í, , "Ṣe ìwọ yóò ọkùnrin yìí lọ."

Ó dáhùn , "Bẹ́̀ ni, èmi yóò lọ."

59 Wọ́n gbà Rebeka àti olùtọ́rẹ̀, pẹ̀ìránṣẹ́ Abrahamu àti àwọn ọkùnrin ó pẹ̀rẹ̀ máa lọ. 60 Wọ́n súre fún Rebeka, wọn fun un ,

"Ìwọ ni arábìnrin wa

ìwọ yóò di ìyá ẹgbẹ̀rún lọ́ẹgbẹ̀rún;

ǹjẹ́ àwọn irú-ọmọ rẹ

ó ni ẹnu ibodè ̀wọn."

61 Nígbà náà ni Rebeka àti àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ múra, wọn gun àwọn ìbákasẹ, wọ́n ọkùnrin náà padà lọ. Ìránṣẹ́ náà Rebeka, ó tirẹ̀ lọ.

62 Isaaki ń ti ̀kànga Lahai-Roi bọ, nítorí ìhà gúúsù ni ó ń gbé. 63 Isaaki jáde lọ oko ni ìrọ̀lẹ́ láti ṣe àṣàrò, ó ti gbé ojú sókè, ó àwọn ìbákasẹ ń bọ̀ . 64 Rebeka pẹ̀gbójú sókè, ó Isaaki. Ó sọ̀kalẹ̀ lórí ìbákasẹ, 65 ó béèrè lọ́wọ́ ìránṣẹ́ náà , "Ta ni ọkùnrin ń bọ̀ pàdé wa láti inú oko?"

Ìránṣẹ́ náà fun un , "Olúwa mi ni," nítorí náà ni Rebeka ìbòjú, ó bo ojú rẹ̀.

66 Nígbà náà ni ìránṣẹ́ náà ròyìn fún Isaaki ohun gbogbo ó ti ṣe. 67 Nígbà náà ni Isaaki Rebeka wọ inú àgọ́ ìyá rẹ̀, Sara, ó di aya rẹ̀, ó fẹ́ràn rẹ̀; ó jẹ́ ìtùnú fún Isaaki lẹ́yìn ikú ìyá rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também