Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 35

Jakọbu padà Beteli

1 35.1: Gẹ 28.11-17. Nígbà náà ni Ọlọ́run fún Jakọbu , "Gòkè lọ Beteli o tẹ̀síbẹ̀, ó mọ pẹpẹ níbẹ̀ fún Ọlọ́run farahàn ́ nígbà o ń sálọ kúrò níwájú Esau arákùnrin rẹ."

2 Nítorí náà, Jakọbu fún gbogbo ará ilé rẹ̀ , "gbogbo àjèjì òrìṣà ó lọ́dọ̀ yín kúrò, ya ara yín mímọ́, pààrọ̀ aṣọ yín. 3 Nígbà náà ni , jẹ́ a lọ Beteli, níbi n ó ti mọ pẹpẹ fún Ọlọ́run, ó mi lóhùn ọjọ́ ìpọ́njú mi ó ti ń pẹ̀mi níbi gbogbo mo ń lọ." 4 Bẹ́̀ ni wọ́n fún Jakọbu gbogbo àjèjì òrìṣà ó lọ́wọ́ wọn, àti yẹtí etí wọn, Jakọbu bo gbogbo wọn mọ́lẹ̀ sábẹ́ igi óákù Ṣekemu. 5 Wọ́n bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò wọn. Ìbẹ̀Ọlọ́run ń bẹ lára gbogbo ìlú ó wọn , wọ́n lépa àwọn ọmọ Jakọbu.

6 Jakọbu àti gbogbo àwọn ó pẹ̀rẹ̀ Lusi (ti o túmọ̀ Beteli) ó ilẹ̀ Kenaani. 7 Níbẹ̀ ni ó mọ pẹpẹ kan ó El-Beteli,35.7 El-Betelití ó túmọ̀ sí Ọlọ́run Beteli nítorí níbẹ̀ ni Ọlọ́run ti gbé fi ara hàn án nígbà ó ń sálọ fún arákùnrin rẹ̀.

8 pẹ́ lẹ́yìn èyí ni Debora, olùtọ́Rebeka , a sin ín sábẹ́ igi óákù ìsàlẹ̀ Beteli. Nítorí náà a sọ ́ Aloni-Bakuti.

9 Lẹ́yìn Jakọbu padà láti Padani-Aramu, Ọlọ́run tún fi ara hàn án, ó súre fún un. 10 Ọlọ́run fun un , "Jakọbu ni orúkọ rẹ, a yóò ́ Jakọbu35.10 Jakọbu tí ó túmọ̀ sí, ajinnilẹ́sẹ̀ mọ́; ṣe Israẹli.35.10 Israẹli tí ó túmọ̀ sí, ẹni tí ó bá Ọlọ́run jìjàkadì. " Nítorí náà, ó sọ orúkọ rẹ̀ Israẹli.

11 Ọlọ́run fún un , "Èmi ni Ọlọ́run alágbára, El-Ṣaddai; máa i, o máa pọ̀ i. Orílẹ̀-èdè àti ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ni yóò ti ̀dọ̀ rẹ̀ , àwọn ọba yóò jáde láti ara rẹ̀. 12 Gbogbo ilẹ̀ mo fi fún Abrahamu àti Isaaki ni èmi yóò fún pẹ̀, àti fún àwọn ìran rẹ ó ń bọ̀ lẹ́yìn." 13 Nígbà náà ni Ọlọ́run gòkè lọ kúrò ibi ó ti ń a sọ̀rọ̀.

14 35.14,15: Gẹ 28.18,19. Jakọbu fi òkúta ṣe ̀wọ̀n kan ibi Ọlọ́run ti a sọ̀rọ̀, ó ta ọrẹ ohun mímu orí rẹ̀, ó da òróró olifi orí rẹ̀ pẹ̀. 15 Jakọbu pe orúkọ ibi Ọlọ́run ti a sọ̀rọ̀ Beteli.

Ikú Rakeli àti Isaaki

16 Nígbà náà ni wọ́n ń tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò wọn láti Beteli. Nígbà ó ku díẹ̀ wọn Efrata, Rakeli bẹ̀rẹ̀ rọbí, ó ìdààmú púpọ̀. 17 ó ti ń rọbí pẹ̀ìrora yìí, agbẹ̀fún un , "bẹ̀nítorí ọmọkùnrin mìíràn ni ó ń bọ̀ yìí." 18 o ti fẹ́ gbé ̀mi, torí ó ń lọ, ó pe ọmọ rẹ̀ náà Bene-Oni, ọmọ ìpọ́njú. Ṣùgbọ́n Jakọbu sọ ọmọ náà Benjamini, ọmọ oókan àyà mi.

19 Báyìí ni Rakeli , a sin ín ̀Efrata (ti o túmọ̀ , Bẹtilẹhẹmu). 20 Jakọbu mọ ̀wọ́n kan ibojì rẹ̀, ̀wọ̀n náà tọ́ka ojú ibojì Rakeli títí di òní.

21 Israẹli ń ìrìnàjò rẹ̀ lọ, ó pa àgọ́ rẹ̀ Migida-Ederi, ilé ìṣọ́ Ederi. 22 35.22: Gẹ 49.4.Nígbà Israẹli ń gbé ibẹ̀, Reubeni wọlé tọ Biliha, àlè baba rẹ̀ lọ, ó a lòpọ̀, Israẹli gbọ́ ̀rọ̀ náà.

Jakọbu ọmọkùnrin méjìlá.

23 Àwọn ọmọ Lea,

Reubeni í ṣe àkọ́Jakọbu,

Simeoni, Lefi, Juda, Isakari àti Sebuluni.

24 Àwọn ọmọ Rakeli:

Josẹfu àti Benjamini.

25 Àwọn ọmọ Biliha ìránṣẹ́bìnrin Rakeli:

Dani àti Naftali.

26 Àwọn ọmọ Silipa ìránṣẹ́bìnrin Lea:

Gadi àti Aṣeri.

Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Jakọbu Padani-Aramu.

27 35.27: Gẹ 13.18. Jakọbu padà ilé lọ́dọ̀ Isaaki baba rẹ̀ ni Mamre nítòsí i Kiriati-Arba (ti o túmọ̀ Hebroni). Níbi Abrahamu àti Isaaki gbé. 28 Ẹni ọgọ́sàn-án ọdún ni Isaaki. 29 Isaaki láìpẹ́ lẹ́yìn ìpadàbọ̀ Jakọbu, a sin ín pẹ̀àwọn ènìyàn rẹ̀ ọjọ́ ogbó rẹ̀. Esau àti Jakọbu ọmọ rẹ̀ sin ín.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também