Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 48

Manase àti Efraimu

1 Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀ si, a fún Josẹfu , "Baba rẹ ń ṣàìsàn," nítorí náà, ó àwọn ọmọ rẹ̀ méjèèjì, Manase àti Efraimu lọ́wọ́ lọ pẹ̀rẹ̀. 2 Nígbà a sọ fún Jakọbu , "Josẹfu ọmọ rẹ ̀dọ̀ rẹ," Israẹli rọ́dìde jókòó lórí ibùsùn rẹ̀.

3 48.3,4: Gẹ 28.13,14. Jakọbu fún Josẹfu , "El-Ṣaddai,48.3 El-Ṣaddai tí ó túmọ̀ sí, Ọlọ́run Olódùmarè fi ara hàn Lusi ilẹ̀ Kenaani, níbẹ̀ ni ó ti súre fún mi. 4 Ó fún mi , Èmi yóò o i, ìwọ yóò pọ̀ i, èmi yóò sọ ́ di orílẹ̀-èdè ńlá, èmi yóò fún ìwọ àti irú-ọmọ rẹ lẹ́yìn rẹ ilẹ̀ yìí gẹ́gẹ́ ohun ìní ayérayé.

5 "Nítorí náà báyìí, àwọn ọmọ rẹ méjèèjì a fún ilẹ̀ Ejibiti, èmi ó tọ̀ ́ ìhín, ni mo sọ di ọmọ mi fúnra mi. Manase àti Efraimu yóò jẹ́ tèmi gẹ́gẹ́ Reubeni àti Simeoni ti jẹ́ tèmi. 6 Àwọn ọmọ mìíràn ìwọ lẹ́yìn wọn yóò jẹ́ ọmọ rẹ. ilẹ̀ wọn yóò jogún, orúkọ arákùnrin wọn ni a ó máa fi wọ́n. 7 48.7: Gẹ 35.16-19.mo ti ń padà láti Padani, Rakeli ̀nígbà ó ṣì ilẹ̀ Kenaani, èyí ìbànújẹ́ mi, níbi jìnnà Efrata. Nítorí náà èmí sin ín ̀̀ó lọ Efrata" (ṣe Bẹtilẹhẹmu).

8 Nígbà Israẹli àwọn ọmọ Josẹfu, ó béèrè , "Àwọn wo nìyí?"

9 Josẹfu fún baba rẹ̀ lésì , "Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin Ọlọ́run ti fi fún mi ìhín."

Nígbà náà ni Israẹli , "wọn ̀dọ̀ mi èmi ó ba à le súre fún wọn."

10 Báyìí, ojú Israẹli ti ń di bàìbàì nítorí ogbó, agbára káká ni ó fi ń ríran. Josẹfu àwọn ọmọ rẹ̀ súnmọ́ ̀dọ̀ rẹ̀, baba rẹ̀ fẹnukò wọ́n ni ẹnu, ó mọ́ wọn.

11 Israẹli fún Josẹfu , "Èmi lérò rárá , mo tún le ojú rẹ mọ́ láéláé, ṣùgbọ́n Ọlọ́run tún fún mi àǹfààní, mo tún àwọn ọmọ rẹ pẹ̀."

12 Nígbà náà ni Josẹfu àwọn ọmọ náà kúrò orí eékún baba rẹ̀, ó wólẹ̀, ó tẹríba. 13 Josẹfu àwọn méjèèjì, Efraimu ni o fi ọwọ́ ̀tún òun tìkára rẹ̀, èyí í ṣe ọwọ́ òsì fún Israẹli, ó fi Manase ọwọ́ òsì ara rẹ̀, èyí ó bọ́ ọwọ́ ̀tún Israẹli. 14 Israẹli na ọwọ́ ̀tún rẹ̀ jáde, ó gbe Efraimu lórí, ó tilẹ̀ jẹ́ òun ni àbúrò, ó fi ọwọ́ rẹ̀ tàsé ara wọn, ó na ọwọ́ òsì Manase lórí, ó tilẹ̀ jẹ́ Manase ni àkọ́.

15 Nígbà náà ni ó súre fún Josẹfu ,

"Ǹjẹ́ Ọlọ́run, ẹni baba mi

Abrahamu àti Isaaki rìn níwájú rẹ̀,

Ọlọ́run ó ti jẹ́ olùtọ́àti aláàbò

mi gbogbo ọjọ́ ayé mi títí di òní,

16 Angẹli ó mi ìdè kúrò lọ́wọ́ gbogbo ewu,

ó súre fún àwọn ọmọkùnrin wọ̀nyí.

a máa fi orúkọ mi wọ́n àti orúkọ àwọn baba mi

Abrahamu àti Isaaki,

wọn ó pọ̀ i lọ́pọ̀lọ́pọ̀

lórí ilẹ̀ ayé."

17 Nígbà Josẹfu i baba òun gbé ọwọ́ ̀tún Efraimu lórí, inú rẹ̀ bàjẹ́, ó gbá ọwọ́ baba rẹ̀ láti gbé ọwọ́ rẹ̀ kúrò lórí Efraimu lọ orí Manase. 18 Josẹfu fun , "Rárá, baba mi, èyí ni àkọ́, orí rẹ̀ ni ìwọ o gbé ọwọ́ ̀tún rẹ ."

19 Ṣùgbọ́n baba rẹ̀ gbà, ó , "Mo mọ̀, ọmọ mi, mo mọ̀. Òun náà yóò di orílẹ̀-èdè, òun náà yóò di ńlá. Ṣùgbọ́n àbúrò rẹ̀ yóò di ẹni ńlá ú lọ, irú-ọmọ rẹ yóò di ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè." 20 48.20: Hb 11.21.Ó súre fún wọn lọ́jọ́ náà ,

"orúkọ yín ni Israẹli yóò máa súre yìí ,

Ọlọ́run ṣe ́ i ti Efraimu àti Manase.’ "

Ó gbé Efraimu gẹ́gẹ́ ̀gbọ́n Manase.

21 Nígbà náà ni Israẹli fún Josẹfu , "Ọjọ́ ikú mi súnmọ́ etílé, ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò pẹ̀yín, yóò un yín padà ilẹ̀ àwọn baba yín. 22 Pẹ̀lúpẹ̀èmi yóò fún ìpín kan ju ti àwọn arákùnrin rẹ lọ. Ilẹ̀ mo fi idà àti ̀kọ̀ mi gbà lọ́wọ́ àwọn ará Amori."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também