Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 19

Ìparun Sodomu àti Gomorra

1 àṣálẹ́, àwọn angẹli méjì ìlú Sodomu, Lọti jókòó ẹnu ibodè ìlú. ó ti wọn, ó dìde láti pàdé wọn, ó wọn, ó foríbalẹ̀ fún wọn. 2 Ó , "̀yin olúwa mi, èmi bẹ̀ yín, ilé ìránṣẹ́ yín wẹ ẹsẹ̀ yín, n gbà yín lálejò, ̀yin ó dìde kùtùkùtù òwúrọ̀ láti máa ìrìnàjò yín lọ."

Wọ́n , "Rárá o, àwa yóò dúró ìgboro òru òní."

3 Ṣùgbọ́n Lọti rọ̀ wọ́n gidigidi bẹ́̀ wọ́n gbà láti a lọ ilé. Ó ṣe àsè fún wọn, ó dín àkàrà aláìwú fún wọ́n, wọ́n jẹ. 4 Ṣùgbọ́n ó di wọ́n lọ sùn, àwọn ọkùnrin ìlú Sodomu tọmọdé tàgbà ilé náà . 5 19.5-8: On 19.22-24.Wọ́n pe Lọti , "Àwọn ọkùnrin ó wọ̀ ilé rẹ lálẹ́ yìí ń kọ́? wọn jáde fún wa, a le ìbálòpọ̀ pẹ̀wọn."

6 Lọti jáde láti pàdé wọn, ó ti ìlẹ̀kùn lẹ́yìn rẹ̀ ó ti jáde. 7 Ó , "Rárá, ̀yin ará mi, ṣe ṣe ohun búburú yìí, 8 kíyèsi i, mo ọmọbìnrin méjì mọ ọkùnrin , jẹ́ n wọn tọ̀ yín ṣe ohun fẹ́ pẹ̀wọn. Ṣùgbọ́n ṣe ṣe àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ibi kan nítorí wọ́n wọ̀ lábẹ́ ààbò ilé mi."

9 Wọ́n fún , "sẹ́yìn fún wa. Èyí yìí ṣe àtìpó láàrín wa, òun fẹ́ ṣe onídàájọ́! Aburú a ó fi ṣe ́ yóò pọ̀ ju wọn lọ." Wọn rọ́ lu Lọti, wọ́n súnmọ́ ọn láti fọ́ ìlẹ̀kùn.

10 Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin náà nawọ́ fa Lọti wọlé, wọ́n ti ìlẹ̀kùn. 11 19.11: 2Ki 6.18.Wọ́n bu ìfọ́lu àwọn ọkùnrin ó ẹnu-ọ̀ilé náà, àti èwe àti àgbà: wọ́n ẹnu-ọ̀mọ́.

12 Àwọn ọkùnrin náà fún Lọti , "Ǹjẹ́ ó ẹlòmíràn ìlú yìí ? Àna rẹ ọkùnrin, àwọn ọmọ rẹ lọ́kùnrin àti lóbìnrin, tàbí ẹnikẹ́ni ìwọ ìlú yìí, wọn jáde kúrò ibí yìí, 13 nítorí a ó pa ìlú yìí run, nítorí igbe iṣẹ́ búburú wọn ń púpọ̀ níwájú Olúwa, Olúwa rán wa láti pa á run."

14 Nígbà náà ni Lọti jáde, ó fún àwọn àna rẹ̀ ọkùnrin ó ti jẹ́ ̀jẹ́ láti fẹ́ àwọn ọmọ rẹ̀ , "ṣe kánkán, jáde ìlú yìí, nítorí Olúwa fẹ́ pa ìlú yìí run!" Ṣùgbọ́n àwọn ọkọ ọmọ rẹ̀ wọ̀nyí àwàdà ń ṣe.

15 àfẹ̀mọ́júmọ́, àwọn angẹli náà rọ Lọti , "Ṣe wéré, aya rẹ àti àwọn ọmọbìnrin rẹ méjèèjì ó níhìn-ín, àìṣe bẹ́̀, ìwọ yóò parun pẹ̀ìlú yìí nígbà wọ́n ń jìyà ̀ṣẹ̀ wọn."

16 19.16: 2Pt 2.7. Nígbà ó ń jáfara, àwọn ọkùnrin náà nawọ́ un lọ́wọ́, wọ́n nawọ́ aya rẹ̀ náà lọ́wọ́ àti àwọn ọmọbìnrin rẹ̀ méjèèjì, wọ́n wọn jáde sẹ́yìn odi ìlú, nítorí Olúwa ṣàánú fún wọn. 17 kété wọ́n wọn jáde sẹ́yìn odi tán, ̀kan nínú wọn , "àsálà fún ̀rẹ! ṣe wo ̀yìn rẹ, bẹ́̀ ni ìwọ ó ṣe dúró gbogbo pẹ̀tẹ́lẹ̀! àsálà lọ orí òkè, ìwọ ó ba ṣègbé!"

18 Ṣùgbọ́n Lọti fún wọn , "Rárá, ̀yin Olúwa mi, jọ̀wọ́! 19 Nígbà ìránṣẹ́ rẹ ti ojúrere rẹ, o ti fi àánú rẹ hàn nípa gbígba ̀mi , èmi le è sálọ sórí òkè, búburú yìí ba à mi , n . 20 ó, ìlú kékeré kan nìyí tòsí láti : jẹ́ n sálọ síbẹ̀, ìlú kékeré ha kọ́? ̀mi yóò ."

21 Ó fún un , "Ó dára, mo gba ̀bẹ̀ rẹ. Èmi yóò run ìlú náà ìwọ sọ̀rọ̀ rẹ̀. 22 Tètè! Sálọ síbẹ̀, nítorí èmi le ṣe ohun kan àyàfi ó ibẹ̀." (ìdí nìyí a fi ń pe ìlú náà Soari).

23 Nígbà Lọti yóò fi ìlú Soari, oòrùn ti yọ. 24 19.24,25: Mt 10.15; 11.23,24; Lk 10.12; 17.29; 2Pt 2.6; On 7.Nígbà náà ni Olúwa rọ̀iná àti sulfuru19.24 tí ó túmọ̀ sí, òkúta iná sórí Sodomu àti Gomorra láti ̀run lọ́dọ̀ Olúwa . 25 Báyìí ni ó run àwọn ìlú náà àti gbogbo ilẹ̀ pẹ̀tẹ́lẹ̀, pẹ̀gbogbo àwọn ó ìlú ńlá ńlá wọ̀n-ọn-nì àti ohun gbogbo ó jáde nílẹ̀. 26 19.26: Lk 17.32.Ṣùgbọ́n aya Lọti bojú wo ̀yìn, ó di ̀wọ́n iyọ̀.

27 kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, Abrahamu dìde ó padà lọ ibi ó gbé dúró níwájú Olúwa. 28 19.28: If 9.2.Ó wo ìhà Sodomu àti Gomorra àti àwọn ilẹ̀ pẹ̀tẹ́lẹ̀ wọ̀n-ọn-nì, ó èéfín ń ti ibẹ̀ jáde èéfín iná ìléru.

29 Ọlọ́run rántí Abrahamu, nígbà ó run ìlú pẹ̀tẹ́lẹ̀ wọ̀n-ọn-nì tan, ó Lọti jáde kúrò láàrín ìparun náà, ó kọlu ìlú Lọti ti gbé.

Lọti àti àwọn ọmọ rẹ̀ obìnrin

30 Lọti àti àwọn ọmọ rẹ̀ obìnrin méjèèjì kúrò Soari, wọ́n ń lọ gbé orí òkè inú ihò àpáta, nítorí ó bẹ̀láti gbé ìlú Soari. 31 ọjọ́ kan, èyí ̀gbọ́n sọ fún àbúrò rẹ̀ , "Baba wa ti dàgbà, ọkùnrin kankan agbègbè yìí ìbá wa lòpọ̀, ìṣe gbogbo ayé. 32 , jẹ́ a baba wa mu ọtí , ó ba à le wa lòpọ̀, àwa ó ọmọ, ìran wa ba à parẹ́."

33 òru ọjọ́ náà, wọ́n rọ baba wọn ọtí . Èyí ̀gbọ́n wọlé tọ̀ ́, ó a lòpọ̀, baba wọn mọ̀ ìgbà ó sùn ti òun àti ìgbà ó dìde.

34 ọjọ́ kejì èyí ̀gbọ́n fún àbúrò rẹ̀ , "àná mo sùn ti baba mi. Jẹ́ a tún wọlé tọ̀ ́, a irú-ọmọ láti ̀dọ̀ baba wa." 35 Bẹ́̀ ni wọ́n tún fún baba wọn ọtí mu ni alẹ́ ọjọ́ náà, èyí àbúrò náà wọlé tọ̀ ́ lọ, ó a lòpọ̀, tún mọ ìgbà ó wọlé sùn ti òun tàbí ìgbà ó dìde.

36 Àwọn ọmọbìnrin Lọti méjèèjì lóyún fún baba wọn. 37 Èyí ̀gbọ́n ọmọkùnrin, ó pe orúkọ rẹ̀ Moabu. Òun ni baba ńlá àwọn ará Moabu lónìí. 38 Èyí àbúrò náà ọmọkùnrin, ó pe orúkọ rẹ̀ Bene-Ami. Òun ni baba ńlá àwọn ará Ammoni lónìí.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também