Pular para o conteúdo
Publicidade

Ìfihàn 17

Obìnrin àti ẹranko

1 17.1: Jr 51.13. ̀kan nínú àwọn angẹli méje náà ó ìgò méje wọ̀n-ọn-nì , ó ba mi sọ̀rọ̀ , "níhìn-ín; èmi ó fi ìdájọ́ àgbèrè ńlá ó jókòó lórí omi púpọ̀ han , 2 17.2: Isa 23.17; Jr 25.15-16.ẹni àwọn ọba ayé ṣe àgbèrè, a fi ọtí wáìnì àgbèrè rẹ̀ pa àwọn ń gbé inú ayé."

3 Ó gbé mi nínú ̀lọ aginjù: mo obìnrin kan ó jókòó lórí ẹranko aláwọ̀ òdòdó kan ó kún fún orúkọ ̀rọ̀-òdì, ó orí méje àti ìwo mẹ́wàá. 4 17.4: Jr 51.7.A fi aṣọ elése àlùkò àti aṣọ òdòdó wọ obìnrin náà, a fi wúrà àti òkúta iyebíye àti perli ṣe é ̀ṣọ́, ó ago wúrà kan ọwọ́ rẹ̀, ó kún fún ìríra àti fún ̀gbin àgbèrè rẹ̀; 5 àti níwájú rẹ̀ ni orúkọ kan a kọ:

Ohun ìjìnlẹ̀ Babeli ńlá

ìyá àwọn panṣágà

àti àwọn ohun ìríra ayé.

6 Mo obìnrin náà mu ̀jẹ̀ àwọn ènìyàn mímọ́, àti ̀jẹ̀ àwọn ajẹ́rìí ikú Jesu àmuyó.

Nígbà mo i, ẹnu mi gidigidi. 7 Angẹli fún mi , "Nítorí ni ẹnu ṣe ́? Èmi ó sọ ti ìjìnlẹ̀ obìnrin náà fún , àti ti ẹranko ó gùn, ti ó orí méje àti ìwo mẹ́wàá. 8 17.8: Da 7.3; If 3.5.Ẹranko ìwọ ri , o ti , ṣí mọ́, yóò ti inú ̀gbun gòkè , yóò lọ sínú ìparun rẹ. Àwọn olùgbé ayé ti a kọ orúkọ wọn sínú ìwé iye láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé, nígbà wọn ń ẹranko o ti , ṣí mọ́, ó ń bọ̀ , ẹnu si ya wọn.

9 "Níhìn-ín ni ìtumọ̀ o ọgbọ́n . Orí méje ni òkè ńlá méje ni, lórí èyí obìnrin náà jókòó. 10 Ọba méje wọn: àwọn márùn-ún ṣubú, ̀kan ń bẹ, ̀kan ìyókù ì ; nígbà ó , yóò dúró fún ìgbà kúkúrú. 11 Ẹranko ó ti , ṣí, òun náà ni ̀kẹjọ, ó ti inú àwọn méje náà , ó lọ ìparun.

12 17.12: Da 7.20-24. "Ìwo mẹ́wàá ìwọ ni ọba mẹ́wàá ni wọn, wọn ì ti gba ìjọba; ṣùgbọ́n wọn gba àṣẹ ọba pẹ̀ẹranko náà fún wákàtí kan. 13 Àwọn wọ̀nyí inú kan, wọ́n yóò fi agbára àti ọlá wọn fún ẹranko náà. 14 17.14: Da 2.47.Àwọn wọ̀nyí ni yóò si máa ̀dọ́-Àgùntàn jagun, ̀dọ́-Àgùntàn náà yóò ṣẹ́gun wọn: nítorí òun ni Olúwa àwọn Olúwa, àti ọba àwọn ọba: àwọn ó pẹ̀rẹ̀, a , a yàn, wọ́n jẹ́ olóòtítọ́ yóò ṣẹ́gun pẹ̀."

15 Ó fún mi , "Àwọn omi ìwọ ti ni, níbi àgbèrè náà jókòó, àwọn ènìyàn àti ̀àti orílẹ̀ àti onírúurú èdè ni wọ́n. 16 Àti ìwo mẹ́wàá ìwọ , àti ẹranko náà, àwọn wọ̀nyí ni yóò kórìíra àgbèrè náà, wọn ó sọ ́ di ahoro àti ẹni ìhòhò, wọn ó jẹ ẹran-ara rẹ̀, wọn ó fi iná sun ún pátápátá. 17 Nítorí Ọlọ́run ti fi sínú ọkàn wọn láti ìfẹ́ rẹ̀ ṣẹ, láti inú kan, àti láti fi ìjọba wọn fún ẹranko náà, títí ̀rọ̀ Ọlọ́run yóò fi ṣẹ. 18 Obìnrin ìwọ ìlú ńlá ni, ń jẹ ọba lórí àwọn ọba ilẹ̀ ayé."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também