Pular para o conteúdo
Publicidade

Ìfihàn 10

Àwọn angẹli àti ìwé kékeré

1 angẹli mìíràn alágbára ò ń ti ̀run sọ̀kalẹ̀ , a fi àwọsánmọ̀ wọ̀ ́ ni aṣọ; òṣùmàrè ń bẹ orí rẹ̀, ojú rẹ̀ dàbí oòrùn, àti ẹsẹ̀ rẹ̀ ̀wọ́n iná. 2 Ó ìwé kékeré kan a ṣí ọwọ́ rẹ̀; ó fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ̀tún Òkun, àti ẹsẹ̀ rẹ̀ òsì ilẹ̀. 3 Ó lóhùn rara, ìgbà kìnnìún ramúramù. Nígbà ó , àwọn àrá méje náà fọhùn. 4 Nígbà àwọn àrá méje fọhùn, mo múra àti kọ̀, mo gbọ́ ohùn láti ̀run ń fún , "Fi èdìdì di ohun àwọn àrá méje náà sọ, ṣe kọ wọ́n sílẹ̀."

5 10.5: De 32.40; Da 12.7. Angẹli náà mo ó dúró lórí Òkun àti lórí ilẹ̀, gbé ọwọ́ rẹ̀ òkè ̀run. 6 Ó fi ẹni ń bẹ láààyè láé àti láé búra, ẹni o ̀run, àti ohun ń bẹ nínú rẹ̀, ayé ohun ń bẹ nínú rẹ̀ , "yóò si ìjáfara mọ́. 7 Ṣùgbọ́n ọjọ́ ohùn angẹli keje, nígbà yóò ba fún ìpè, nígbà náà ni ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run, gẹ́gẹ́ o sọ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àwọn wòlíì ni a ó ṣẹ."

8 Ohùn náà mo gbọ́ láti ̀run tún ń ba mi sọ̀rọ̀, ó , "Lọ, gba ìwé o ṣí lọ́wọ́ angẹli o dúró lórí Òkun àti lórí ilẹ̀."

9 10.9: El 2.8; 3.1-3. Mo tọ angẹli náà lọ, mo fún , "Fún mi ìwé kékeré náà." Ó fún mi , "Gbà o jẹ ́ tan: yóò dàbí oyin." 10 Mo gba ìwé kékeré náà ni ọwọ́ angẹli náà mo jẹ ́ tan; ó dùn lẹ́nu mi oyin; mo jẹ ́ tan, inú mi korò. 11 10.11: Jr 1.10.A fún mi , "Ìwọ ó tún sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, àti orílẹ̀ àti èdè, àti àwọn ọba."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também