Pular para o conteúdo
Publicidade

Nehemiah 10

1 Àwọn ó fi èdìdì í ni:

Nehemiah baálẹ̀, ọmọ Hakaliah.

Sedekiah 2 Seraiah, Asariah, Jeremiah,

3 Paṣuri, Amariah, Malkiah,

4 Hattusi, Ṣebaniah, Malluki,

5 Harimu, Meremoti, Obadiah,

6 Daniẹli, Ginetoni, Baruku,

7 Meṣullamu, Abijah, Mijamini,

8 Maasiah, Bilgai àti Ṣemaiah.

Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà.

9 Àwọn ọmọ Lefi:

Jeṣua ọmọ Asaniah, Binnui ̀kan nínú àwọn ọmọ Henadadi, Kadmieli,

10 àti àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn: Ṣebaniah,

Hodiah, Kelita, Pelaiah, Hanani,

11 Mika, Rehobu, Haṣabiah,

12 Sakkuri, Ṣerebiah, Ṣebaniah,

13 Hodiah, Bani àti Beninu.

14 Àwọn olórí àwọn ènìyàn:

Paroṣi, Pahati-Moabu, Elamu, Sattu, Bani,

15 Bunni, Asgadi, Bebai.

16 Adonijah, Bigfai, Adini,

17 Ateri, Hesekiah, Assuri,

18 Hodiah, Haṣumu, Besai,

19 Harifu, Anatoti, Nebai,

20 Magpiaṣi, Meṣullamu, Hesiri

21 Meṣesabeli, Sadoku, Jaddua

22 Pelatiah, Hanani, Anaiah,

23 Hosea, Hananiah, Haṣubu,

24 Halloheṣi, Pileha, Ṣobeki,

25 Rehumu, Haṣabna, Maaseiah,

26 Ahijah, Hanani, Anani,

27 Malluki, Harimu, àti Baanah.

28 "Àwọn ènìyàn tókùàwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi, àwọn aṣọ́, àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti gbogbo àwọn wọ́n ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn àjèjì nítorí òfin Ọlọ́run, papọ̀ pẹ̀ìyàwó wọn, gbogbo ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọn, òye 29 gbogbo wọn fi ara mọ́ àwọn arákùnrin wọn, àwọn ọlọ́, wọ́n fi ègún àti ìbúra ara wọn láti máa tẹ̀òfin Ọlọ́run a fi fún wọn ipasẹ̀ Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run àti láti pa gbogbo àṣẹ, ìlànà àti òfin Olúwa, wa mọ́ dáradára.

30 "A ti ṣe ìlérí , a fi àwọn ọmọbìnrin wa fún àwọn wọ́n àyíká wa ìyàwó, tàbí fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin wa.

31 "Nígbà àwọn ènìyàn àdúgbò ọjà tàbí oúnjẹ ọjọ́ ìsinmi láti , àwa á ọwọ́ wọn ọjọ́ ìsinmi tàbí ọjọ́ mímọ́ kankan. gbogbo ọdún keje àwa ro ilẹ̀ náà, a ó pa gbogbo àwọn gbèsè rẹ́.

32 "Àwa gbà ojúṣe láti máa pa àṣẹ mọ́ , a ó máa san ìdámẹ́ta ṣékélì ọdọọdún fún iṣẹ́ ilé Ọlọ́run wa: 33 nítorí oúnjẹ ó lórí tábìlì; nítorí ọrẹ ohun jíjẹ àti ẹbọ sísun ìgbà gbogbo; nítorí ọrẹ ọjọ́ ìsinmi, ti àyajọ́ oṣù tuntun àti àjọ̀dún a yàn; nítorí ọrẹ mímọ́; nítorí ọrẹ ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù fún Israẹli; àti fún gbogbo iṣẹ́ ilé Ọlọ́run wa.

34 "Àwa, àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi àti àwọn ènìyàn náà ti dìbò láti pinnu ìgbà olúkúlùkù àwọn ìdílé yóò ọrẹ igi láti sun lọ́ríi pẹpẹ Olúwa Ọlọ́run wa ilé Ọlọ́run wa, àkókò a yàn ọdọọdún. Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ sínú ìwé òfin.

35 "Àwa tún gbà ojúṣe láti àkọ́so àwọn èso wa àti gbogbo èso igi ilé Olúwa.

36 "Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ sínú ìwé òfin, àwa yóò àkọ́àwọn ọmọkùnrin wa, ti ohun ̀sìn wa, ti àwọn abo màlúù àti ti àwọn àgùntàn wa, ilé Ọlọ́run wa, fún àwọn àlùfáà ń ṣiṣẹ́ níbẹ̀.

37 "Síwájú i, àwa yóò àkọ́so oúnjẹ ilẹ̀ wa ti ọrẹ oúnjẹ, ti gbogbo èso àwọn igi àti ti wáìnì tuntun wa àti ti òróró yàrá ìkó nǹkan pamọ́ ilé Ọlọ́run wa àti fún àwọn àlùfáà. Àwa yóò ìdámẹ́wàá ohun ̀gbìn fún àwọn ọmọ Lefi, nítorí àwọn ọmọ Lefi ni ó ń gba ìdámẹ́wàá gbogbo àwọn ìlú a ti ń ṣiṣẹ́. 38 Àlùfáà o ti ìdílé Aaroni ni yóò pẹ̀àwọn ọmọ Lefi nígbà wọ́n ń gba ìdámẹ́wàá, àwọn ọmọ Lefi yóò ìdámẹ́wàá ti ìdámẹ́wàá náà ilé Ọlọ́run, yàrá ìkó nǹkan pamọ́ inú ilé ìṣúra. 39 Àwọn ènìyàn Israẹli, àti àwọn ọmọ Lefi gbọdọ̀ ọrẹ oúnjẹ, wáìnì tuntun àti òróró yàrá ìkó nǹkan pamọ́ níbi a pa ohun èlò ibi mímọ́ mọ́ àti ibi àwọn àlùfáà ń ṣe ìránṣẹ́ lọ́wọ́, àwọn aṣọ́àti àwọn akọrin máa ń dúró .

"Àwa yóò gbàgbé tàbí ṣe àìbìkítà nípa ilé Ọlọ́run wa."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também