Pular para o conteúdo
Publicidade

Nehemiah 6

Àwọn ̀dáwọ́ àtakò dúró

1 Nígbà Sanballati, Tobiah Geṣemu ará Arabia àti àwọn ̀wa tókù gbọ́ , mo ti tún odi náà mọ, àlàfo kankan ó ṣẹ́nínú rẹ̀—ó tilẹ̀ jẹ́ èmi ì ì ri àwọn ìlẹ̀kùn ibodè àkókò náà. 2 Sanballati àti Geṣemu rán iṣẹ́ yìí mi , "jẹ́ a jọ pàdé pọ̀ nínú ̀kan lára àwọn ìletò pẹ̀tẹ́lẹ̀ Ono."

Ṣùgbọ́n wọ́n ń gbèrò láti ṣe ibi; 3 bẹ́̀ ni mo rán oníṣẹ́ padà pẹ̀èsì yìí , "Èmi ń ṣe iṣẹ́ ńlá kan, èmi le è sọ̀kalẹ̀ . Èéṣe iṣẹ́ náà yóò fi dúró, nígbà mo fi í sílẹ̀ mo sọ̀kalẹ̀ tọ̀ yín ?" 4 Wọ́n rán iṣẹ́ náà mi nígbà mẹ́rin ̀tọ̀̀tọ̀, mo fún wọn èsì bákan náà fún ìgbà kọ̀̀kan.

5 ìgbà karùn-ún, Sanballati rán ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ mi pẹ̀irú iṣẹ́ kan náà, lẹ́kan a fi sínú àpò ìwé ọwọ́ rẹ̀ 6 a kọ sínú un rẹ̀ ,

"A ròyìn rẹ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, Geṣemu sọ , òtítọ́ ni, ìwọ àti àwọn Júù ń gbèrò láti ṣọ̀tẹ̀, nítorí náà ni ṣe ń mọ odi. Síwájú i, gẹ́gẹ́ ìròyìn yìí, ìwọ ń gbèrò láti di ọba wọn 7 àti ó ti yan àwọn wòlíì wọn kéde nípa rẹ̀ Jerusalẹmu: Ọba kan Juda!Nísinsin yìí, ìròyìn yìí yóò padà ̀dọ̀ ọba; nítorí náà , jẹ́ a ara wa sọ̀rọ̀."

8 Mo èsì yìí padà i , "ohun kan nínú irú ohun ìwọ sọ ó ṣẹlẹ̀; ìwọ kàn wọ́n orí ara rẹ ni."

9 Gbogbo wọn múra láti dẹ́rùbà , wọ́n ń ó , "Ọwọ́ wọn ran iṣẹ́ náà, àti wọn parí rẹ̀."

Ṣùgbọ́n mo gbàdúrà , "Nísinsin yìí Ọlọ́run fi agbára fún ọwọ́ mi."

10 ọjọ́ kan mo lọ ilé Ṣemaiah ọmọ Delaiah, ọmọ Mehetabeeli, ẹni a mọ́ sínú ilé rẹ̀. Ó , "Jẹ́ a pàdé ilé Ọlọ́run nínú tẹmpili, o jẹ́ a pa àwọn ìlẹ̀kùn tẹmpili , nítorí àwọn ènìyàn ń bọ̀ láti pa ́, òru ni wọn yóò láti pa ́."

11 Ṣùgbọ́n mo , "Ǹjẹ́ ó yẹ irú ènìyàn èmi sálọ? Tàbí ènìyàn èmi sálọ sínú tẹmpili láti gba ̀ara rẹ̀ ? Èmi lọ!" 12 Èmi wòye Ọlọ́run rán an, ṣùgbọ́n ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ mi nítorí Tobiah àti Sanballati ti bẹ̀ ́ ̀wẹ̀. 13 Wọ́n bẹ̀ ́ ̀wẹ̀ láti dẹ́rùbà nítorí èmi dẹ́ṣẹ̀ nípa ṣíṣe èyí, wọn lórúkọ jẹ́, n di ẹni ̀gàn.

14 A! Ọlọ́run mi, rántí Tobiah àti Sanballati, nítorí ohun wọ́n ti ṣe; o tún rántí Noadiah wòlíì obìnrin àti àwọn wòlíì tókù wọ́n ń gbèrò láti dẹ́rùbà . 15 Bẹ́̀ ni a parí odi náà ọjọ́ kẹẹdọ́gbọ̀n oṣù Eluli,6.15 tí ó túmọ̀ sí, oṣù kẹsànán láàrín ọjọ́ méjìléláàádọ́ta.

Píparí odi

16 Nígbà àwọn ̀wa gbọ́ èyí, gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ó wa bẹ̀jìnnìjìnnì wọn, nítorí wọ́n wòye iṣẹ́ yìí di ṣíṣe pẹ̀ìrànlọ́wọ́ Ọlọ́run wa.

17 Bákan náà, ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àwọn ọlọ́Juda ń kọ ̀pọ̀lọpọ̀ lẹ́ránṣẹ́ Tobiah, èsì láti ̀dọ̀ Tobiah ń ̀dọ̀ wọn. 18 Nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn Juda ti mulẹ̀ pẹ̀rẹ̀, nítorí ó jẹ́ àna Ṣekaniah ọmọ Arah (Sanballati fẹ́ ọmọ Ṣekaniah), ọmọ rẹ̀ Jehohanani tún fẹ́ ọmọbìnrin Meṣullamu ọmọ Berekiah. 19 Síwájú í, wọ́n túbọ̀ ń ròyìn iṣẹ́ rere rẹ̀ fún mi, wọ́n ń sọ ohun mo sọ fún un. Tobiah ń kọ àwọn lẹ́ránṣẹ́ mi láti dẹ́rùbà .

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também