Pular para o conteúdo
Publicidade

Onidajọ 17

Ìbọ̀rìṣà Mika

1 Nígbà náà ni ọkùnrin kan orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mika láti agbègbè òkè Efraimu 2 sọ fún ìyá rẹ̀ , "̀́dẹ́gbẹ̀ṣékélì fàdákà èyí wọ́n mọ́ lọ́wọ́, àti nípa èyí mo gbọ́ ìwọ ń ṣẹ́ èpè. Kíyèsi fàdákà náà ̀dọ̀ mi, èmi ni mo o."

Nígbà náà ni ìyá rẹ̀ dáhùn , "Olúwa bùkún ọmọ mi!"

3 Nígbà ó da ̀́dẹ́gbẹ̀ṣékélì fàdákà náà padà fún ìyá rẹ̀, ìyá rẹ̀ dáhùn , "Èmi ti fi òtítọ́ inú ya sílífà náà sọ́tọ̀ Olúwa fún ọmọ mi láti fi ère dídá àti ère gbígbẹ́. Èmi yóò a padà fún ."

4 Nítorí náà òun sílífà náà padà fún ìyá rẹ̀, ìyá rẹ̀ igba ṣékélì fàdákà, ó fún alágbẹ̀dẹ fàdákà ẹni ó fi wọ́n rọ ère fínfín àti ère dídà. Wọ́n wọn ilé Mika.

5 Ọkùnrin náà, Mika ojúbọ kan. Òun ra ̀efodu kan, ó ṣe àwọn ère kan, ó fi ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin ṣe àlùfáà rẹ̀. 6 ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àwọn ọmọ Israẹli ọba; olúkúlùkù ṣe ó ti ó tọ́ ojú ara rẹ́.

7 ̀dọ́mọkùnrin kan ti Bẹtilẹhẹmu ti Juda , í ṣe ìdílé Juda, ẹni í ṣe ̀Lefi, òun ṣe àtìpó níbẹ̀, 8 ọkùnrin náà ti ìlú Bẹtilẹhẹmu ti Juda lọ, láti ṣe àtìpó ibikíbi ó . ojú ̀àjò rẹ̀, ó ilẹ̀ Mika nínú àwọn ilẹ̀ òkè Efraimu.

9 Mika bi í , "Níbo ni ó ti ń bọ̀?"

Ó dáhùn , "Ọmọ Lefi ni láti Bẹtilẹhẹmu Juda, mo ń ibi èmi yóò máa gbé."

10 Mika sọ fún un , "Dúró lọ́dọ̀ mi ìwọ jẹ́ baba mi àti àlùfáà fún mi, èmi ó máa fún ṣékélì mẹ́wàá fàdákà ọdọọdún, pẹ̀aṣọ àti oúnjẹ rẹ̀." 11 Ọmọ Lefi náà gbà láti máa a gbé, ̀dọ́mọkùnrin náà dàbí ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀. 12 Nígbà náà ni Mika ya ará Lefi náà mímọ́, ̀dọ́mọkùnrin náà di àlùfáà rẹ̀, ó ń gbé ilé rẹ̀. 13 Mika , "Báyìí, èmi mọ̀ Olúwa yóò ṣe mi oore nítorí mo ọmọ Lefi àlùfáà mi."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também