Pular para o conteúdo
Publicidade

Onidajọ 10

Tola

1 Lẹ́yìn ikú Abimeleki, ọkùnrin kan láti ̀Isakari orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Tola ọmọ Pua, ọmọ Dodo, dìde láti gba Israẹli sílẹ̀. Ṣamiri ó òkè Efraimu ni ó gbé. 2 Ó ṣe àkóso Israẹli ọdún mẹ́tàlélógún. Nígbà ó wọ́n sìn ín Ṣamiri.

Jairi

3 Jairi ti ̀Gileadi ni ó dìde lẹ́yìn rẹ̀, ó ṣàkóso Israẹli ọdún méjìlélógún. 4 Àwọn ọgbọ̀n ọmọ ó n gun ọgbọ̀n kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́. Wọ́n ṣe àkóso ọgbọ̀n ìlú Gileadi, a pe orúkọ wọn Hafoti-Jairi títí di òní. 5 Nígbà Jairi wọ́n sin ín Kamoni.

Jefta

6 Àwọn ọmọ Israẹli túnṣe ohun ó burú lójú Olúwa. Wọ́n sin Baali àti Aṣtoreti àti àwọn òrìṣà Aramu, òrìṣà Sidoni, òrìṣà Moabu, òrìṣà àwọn ará Ammoni àti òrìṣà àwọn ará Filistini. Nítorí àwọn ará Israẹli kọ Olúwa sílẹ̀ wọn sìn ín mọ́, 7 ó bínú wọn, ó fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn ará Filistini àti Ammoni láti jẹ ́ ìyà. 8 ọdún náà, wọ́n wọn wọ́n pọ́n wọn lójú. Fún ọdún méjìdínlógún ni wọ́n fi ni gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ó ìlà-oòrùn odò Jordani ilẹ̀ àwọn ará Amori lára (èyí Gileadi). 9 Àwọn ará Ammoni la odò Jordani kọjá láti Juda, Benjamini àti àwọn ará ilé Efraimu jagun: Israẹli dojúkọ ìpọ́njú lágbára. 10 Nígbà èyí ti ṣẹlẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli pe Olúwa , "Àwa ti ṣẹ̀ , nítorí àwa ti kọ Ọlọ́run wa sílẹ̀, àwa ń sin Baali."

11 Olúwa dáhùn , "Ǹjẹ́ nígbà àwọn ará Ejibiti, Amori, Ammoni, Filistini, 12 àwọn ará Sidoni, Amaleki pẹ̀Maoni ni yín lára, fún ìrànlọ́wọ́, ǹjẹ́ èmi gbà yín sílẹ̀ kúrò ọwọ́ wọn? 13 Síbẹ̀síbẹ̀ ̀yin kọ̀ sílẹ̀ láti sin àwọn ọlọ́run mìíràn, torí ìdí èyí, èmi yóò tún gbà yín mọ́. 14 lọ pe àwọn òrìṣà ̀yin ti yàn fún ara yín. Jẹ́ wọn gbà yín sílẹ̀ àsìkò ìpọ́njú yín!"

15 Àwọn ọmọ Israẹli Olúwa lóhùn , "Àwa ti ṣẹ̀, ṣe ohun ó fẹ́ pẹ̀wa, ṣùgbọ́n, jọ̀wọ́ gbà sílẹ̀ náání àsìkò yìí." 16 Nígbà náà ni wọ́n gbogbo ọlọ́run àjèjì ó láàrín wọn kúrò wọ́n sin Olúwa nìkan, ọkàn rẹ̀ le gbàgbé ìrora Israẹli mọ́.

17 Nígbà àwọn ará Ammoni kógun jọ Gileadi láti Israẹli , àwọn ọmọ Israẹli gbárajọpọ̀, wọ́n tẹ̀ogun Mispa. 18 Àwọn ìjòyè: aṣíwájú àwọn ará Gileadi fún ará wọn , "Ẹnikẹ́ni yóò kọ́ ṣígun si àwọn ará Ammoni ni yóò jẹ́ orí fún gbogbo àwọn ń gbé Gileadi."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também