Pular para o conteúdo
Publicidade

Onidajọ 8

Seba àti Salmunna

1 Àwọn àgbàgbà ̀Efraimu bínú gidigidi Gideoni wọ́n bi í léèrè , o fi ṣe irú èyí wa? Èéṣe ìwọ fi nígbà ìwọ kọ́kọ́ jáde lọ láti àwọn ará Midiani jagun? Ohùn ìbínú ni wọ́n fi a sọ̀rọ̀.

2 Ṣùgbọ́n Gideoni wọn lóhùn , "Àṣeyọrí wo ni mo ti ṣe ó fiwé tiyín? Àṣàkù àjàrà Efraimu ha dára ju gbogbo ìkórè àjàrà Abieseri lọ ? 3 Ọlọ́run ti fi Orebu àti Seebu àwọn olórí àwọn ará Midiani yín lọ́wọ́. ni ohun Mose ṣe ó fiwé e yín tàbí ó àṣeyọrí i yín?" Nígbà ó èyí ríru ìbínú wọn rọlẹ̀.

4 Gideoni àti àwọn ̀́dúnrún (300) ọkùnrin ó pẹ̀rẹ̀ tẹ̀síwájú láti lépa àwọn ̀ó tilẹ̀ jẹ́ ó ti rẹ̀ wọ́n, wọ́n Jordani wọ́n kọjá òdìkejì. 5 Ó fún àwọn ọkùnrin Sukkoti , "fún àwọn ọmọ-ogun mi oúnjẹ díẹ̀, nítorí ó ti rẹ̀ wọ́n, èmi ń lépa Seba àti Salmunna àwọn ọba Midiani."

6 Ṣùgbọ́n àwọn ìjòyè Sukkoti fèsì ṣé ọwọ́ rẹ ti tẹ Seba àti Salmunna náà ni? Èéṣe àwa yóò ṣe fún àwọn ológun rẹ oúnjẹ?

7 Gideoni wọn lóhùn , "Ó dára, nígbà Olúwa fi Seba àti Salmunna mi lọ́wọ́ tán èmi yóò fi ̀gún ijù àti ̀gún òṣùṣú ya ẹran-ara yín."

8 Láti ibẹ̀, ó lọ Penieli ó bẹ̀ wọ́n bẹ́̀ gẹ́gẹ́, ṣùgbọ́n àwọn náà a lóhùn àwọn ará Sukkoti ti a lóhùn. 9 Nígbà náà ni ó sọ fún àwọn ọkùnrin Penieli , "Nígbà mo ṣẹ́gun mo padà àlàáfíà, èmi yóò ilé ìṣọ́ yìí."

10 àsìkò náà Seba àti Salmunna Karkori pẹ̀ọmọ-ogun wọn ó ẹgbẹ̀rún mẹ́̀́dógún (15,000) ọkùnrin, àwọn wọ̀nyí ni ó ṣẹ́nínú gbogbo ogun àwọn ènìyàn apá ìlà-oòrùn, nítorí ̀kẹ́ mẹ́(120,000) ọkùnrin ó fi idà ti ojú ogun. 11 Gideoni gba ̀àwọn darandaran máa ń rìn apá ìhà ìlà-oòrùn Noba àti Jogbeha ó kọjú ogun àwọn ọmọ-ogun náà nítorí wọ́n ti túra sílẹ̀. 12 Seba àti Salmunna, àwọn ọba Midiani méjèèjì , ṣùgbọ́n Gideoni lépa wọn ó wọn, ó run gbogbo ogun wọn.

13 Gideoni ọmọ Joaṣi gba ̀ìgòkè Heresi padà sẹ́yìn láti ojú ogun. 14 Ó ̀dọ́mọkùnrin kan ará Sukkoti, ó béèrè àwọn ìbéèrè ọwọ́ rẹ̀, ̀dọ́mọkùnrin náà kọ orúkọ àwọn ìjòyè Sukkoti mẹ́tàdínlọ́gọ́rin fún un wọ́n jẹ́ àgbàgbà ìlú náà. 15 Nígbà náà ni Gideoni ó sọ fún àwọn ọkùnrin Sukkoti , "Seba àti Salmunna nìwọ̀nyí nípa àwọn ̀yin fi ṣẹ̀fẹ̀ nígbà , Ṣé ó ti ṣẹ́gun Seba àti Salmunna? Èéṣe àwa ó fi fún àwọn ọmọ-ogun rẹ ó ti rẹ̀ oúnjẹ?’ " 16 Ó àwọn àgbàgbà ìlú náà, ó fi kọ́ àwọn Sukkoti lọ́gbọ́n nípa jíjẹ wọ́n pẹ̀àwọn ̀gún ijù àti ̀gún ̀gàn. 17 Ó ilé ìṣọ́ Penieli, ó pa àwọn ọkùnrin ìlú náà.

18 Gideoni bi Seba àti Salmunna , "Irú ọkùnrin pa Tabori, báwo ni wọ́n ṣe ?"

"Àwọn ọkùnrin náà dàbí rẹ ̀kọ̀̀kan wọn dàbí ọmọ ọba," ìdáhùn wọn.

19 Gideoni dáhùn , "Arákùnrin mi ni wọ́n, àwọn ọmọ ìyá mi. Mo fi Olúwa búra, ó ṣe ̀wọn , èmi náà ò nípa yín." 20 Ó padà Jeteri, ọmọ rẹ̀ ó dàgbà jùlọ, ó fún un , "Pa wọ́n!" Ṣùgbọ́n Jeteri fa idà rẹ̀ yọ láti pa wọ́n nítorí ó jẹ́ ̀dọ́mọdé ̀á láti pa wọ́n.

21 Seba àti Salmunna Gideoni lóhùn , "pa fún raàrẹ, Nítorí ènìyàn ti bẹ́̀ ni agbára rẹ̀ yóò .’ " Gideoni bọ́ síwájú ó pa wọ́n, ó ohun ̀ṣọ́ ó ọrùn àwọn ìbákasẹ wọn.

Efodu Gideoni

22 Àwọn ará Israẹli fún Gideoni , "Jọba lórí waìwọ, àwọn ọmọ rẹ àti àwọn ọmọ ọmọ rẹ pẹ̀, nítorí ìwọ ti gbà lọ́wọ́ àwọn ará Midiani."

23 Ṣùgbọ́n Gideoni wọn lóhùn , "Èmi yóò jẹ ọba lórí yín, bẹ́̀ ni àwọn ọmọ mi yóò jẹ ọba lórí yín. Olúwa ni yóò jẹ ọba lórí yín." 24 Gideoni , "Mo ̀bẹ̀ kan mo fẹ́ bẹ̀ yín ẹnìkọ̀̀kan yín fún mi yẹtí kọ̀̀kan láti inú ohun ti ó kàn yín láti inú ìkógun." (Àṣà àwọn ará Iṣmaeli ni láti máa fi yẹtí wúrà sétí.)

25 Wọ́n dáhùn , "Tayọ̀tayọ̀ ni àwa yóò fi wọ́n sílẹ̀." Wọ́n tẹ́ aṣọ kan sílẹ̀ ọkùnrin kọ̀̀kan ń sọ yẹtí kọ̀̀kan ó kàn wọ́n láti ibi ìkógun síbẹ̀. 26 Ìwọ̀n òrùka wúrà ó béèrè fún ̀́dẹ́gbẹ̀sán (1,700) ìwọ̀n ṣékélì, láìka àwọn ohun ̀ṣọ́ àti ohun sísorọ̀ ó lára ìlẹ̀kẹ̀ ọrùn àti aṣọ elése àlùkò àwọn ọba Midiani ń wọ̀ tàbí àwọn ̀wọ̀n ó ọrùn àwọn ìbákasẹ wọn. 27 Gideoni fi àwọn wúrà náà ṣe efodu èyí ó gbé kalẹ̀ Ofira ìlú rẹ̀. Àwọn ọmọ Israẹli sọ ara wọn di àgbèrè nípa sínsin-ín ibẹ̀. Ó di ìdẹ̀kùn fún Gideoni àti ìdílé rẹ̀.

Ikú Gideoni

28 Báyìí ni a ṣe tẹrí àwọn ará Midiani ba níwájú àwọn ọmọ Israẹli bẹ́̀ ni wọn tún gbé orí mọ́. ọjọ́ Gideoni, Israẹli àlàáfíà fún ogójì ọdún.

29 Jerubbaali ọmọ Joaṣi padà lọ láti máa gbé ìlú rẹ̀. 30 Àádọ́rin ọmọ ni Gideoni , nítorí ó ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ìyàwó. 31 Àlè rẹ̀, ń gbé Ṣekemu, pàápàá ọmọkùnrin kan fún un ó pe orúkọ rẹ̀ Abimeleki. 32 Gideoni ọmọ Joaṣi ògbólógbòó ọjọ́ rẹ̀, ó pọ̀ ọjọ́ orí, wọ́n sin ín ibojì baba rẹ̀ Ofira ti àwọn ará Abieseri.

33 Láìpẹ́ jọjọ lẹ́yìn ikú Gideoni ni àwọn ará Israẹli ṣe àgbèrè tọ Baali lẹ́yìn, wọ́n fi Baali-Beriti ṣe òrìṣà wọn. 34 Wọn rántí Olúwa Ọlọ́run wọn, ẹni ó gbà wọ́n kúrò lọ́wọ́ àwọn ̀wọn gbogbo ó gbogbo àyíká wọn. 35 Wọ́n kùnà láti fi inú rere hàn ìdílé Jerubbaali (èyí ni Gideoni) fún gbogbo oore ó ṣe fún wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também