Pular para o conteúdo
Publicidade

Onidajọ 18

Àwọn ìran Dani tẹ̀Laiṣi

1 ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, àwọn ọmọ Israẹli ọba.

ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, àwọn ̀Dani ń ilẹ̀ tiwọn, níbi wọn yóò máa gbé, nítorí títí di àkókò náà wọn ì ì pín ogún ilẹ̀ fún wọn ìní láàrín àwọn ọmọ Israẹli. 2 Nítorí náà àwọn ̀Dani rán àwọn jagunjagun márùn-ún lọ láti Sora àti Eṣtaoli láti yọ́ ilẹ̀ náà àti láti rìn ín . Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ṣe ojú fún gbogbo àwọn ̀wọn. Wọ́n fún wọn , "lọ rin ilẹ̀ náà , ó fínní fínní."

Àwọn ọkùnrin náà wọ àwọn ìlú ó agbègbè òkè Efraimu, wọ́n ilé Mika, níbi wọ́n sùn òru náà. 3 Nígbà wọ́n súnmọ́ tòsí ilé e Mika, wọ́n ohùn ̀dọ́mọkùnrin Lefi náà mọ̀, torí náà wọ́n yípadà, wọ́n wọ inú ilé náà lọ wọ́n bi í , "ni ó wa ibi? ni ìwọ ń ṣe níhìn-ín yìí? Èéṣe o fi ibí?"

4 Ó sọ ohun Mika ti ṣe fún un, ó fi kún un fún wọn , "Ó gbà iṣẹ́, èmi ni àlùfáà rẹ̀."

5 Wọ́n fún un , "Jọ̀wọ́ béèrè ọwọ́ Ọlọ́run, àwa mọ̀ ìrìnàjò wa yóò yọrí rere."

6 Àlùfáà náà wọn lóhùn , "máa lọ àlàáfíà. Ìrìnàjò yín ̀yin ń rìn ojúrere Olúwa pàdé."

7 Àwọn ọkùnrin márààrún náà kúrò, wọ́n Laiṣi, níbi wọ́n ti i àwọn ènìyàn ń gbé ibẹ̀ ààbò, àwọn ará Sidoni, láìsí ìfòyà àti ìpamọ́. ìgbà ilẹ̀ wọn ṣe aláìní ohunkóhun, wọ́n ọrọ̀ púpọ̀. Ibùgbé wọn tún jìnnà ti àwọn ará Sidoni, wọn fi ohunkóhun ẹnikẹ́ni dàpọ̀.

8 Nígbà wọ́n padà Sora àti Eṣtaoli, àwọn arákùnrin wọn bi wọ́n léèrè , "Báwo ni ibi lọ ti ? ni ìròyìn ?"

9 Wọ́n dáhùn , "dìde jẹ́ a lọ kọlù wọ́n! A i ilẹ̀ náà dára gidigidi. Ṣé ̀yin ó jókòó láìsí nǹkan nípa rẹ̀? ṣe lọ́ra láti lọ síbẹ̀ gba ilẹ̀ náà. 10 Nígbà ̀yin ibẹ̀, yóò àwọn ènìyàn ọkàn wọn balẹ̀ àti ilẹ̀ ó tẹ́Ọlọ́run ti fi fún yín, ilẹ̀ ṣe aláìní nǹkan kan."

11 Nígbà náà ni ẹgbẹ̀ta (600) ọkùnrin ó múra ogun láti ìran Dani, jáde lọ láti Sora àti Eṣtaoli mímú ra láti jagun. 12 Wọ́n jáde lọ, ojú ̀wọn, wọ́n tẹ̀ogun ̀Kiriati-Jearimu Juda. Ìdí nìyí wọ́n fi ń gbé ìwọ̀-oòrùn Kiriati-Jearimu ni Mahane-Dani títí di òní yìí. 13 Láti ibẹ̀ wọ́n kọjá lọ àwọn ìlú agbègbè òkè Efraimu, wọ́n ilé Mika.

14 Nígbà náà ni àwọn ọkùnrin márùn-ún ó lọ yọ́ ilẹ̀ Laiṣi sọ fún àwọn arákùnrin wọn , "Ǹjẹ́ ̀yin mọ̀ ̀kan nínú àwọn ilé yìí ̀efodu, àwọn yòókù òrìṣà, ère gbígbẹ́ àti ère dídà? mọ ohun ó yẹ ṣe báyìí." 15 Wọ́n ibẹ̀, wọ́n wọ ilé ̀dọ́mọkùnrin Lefi náà, ilé Mika, wọ́n béèrè àlàáfíà rẹ̀. 16 Àwọn ẹgbẹ̀ta (600) ọkùnrin ará Dani náà ó hámọ́ra ogun, dúró àbáwọlé ẹnu odi. 17 Àwọn ọkùnrin márùn-ún wọ́n lọ yọ́ ilẹ̀ náà wọlé lọ wọ́n ère gbígbẹ́ náà, efodu náà, àwọn òrìṣà ìdílé àti ère dídà náà nígbà àlùfáà náà àti àwọn ẹgbẹ̀ta (600) ọkùnrin ó hámọ́ra ogun dúró à wọ ẹnu odi náà.

18 Nígbà àwọn ọkùnrin yìí wọ ilé e Mika lọ wọ́n ère fínfín náà, efodu náà, àwọn òrìṣà ìdílé mìíràn àti ère dídà náà, àlùfáà náà béèrè lọ́wọ́ wọn , "ni ̀yin ń ṣe?"

19 Wọ́n a lóhùn , "Dákẹ́! Ma sọ nǹkan kan, tẹ̀wa o di baba àti àlùfáà wa. ha sàn fún láti máa ṣe ìránṣẹ́ ̀àti ìdílé kan ó láti Israẹli àlùfáà ju ilé ẹnìkan ṣoṣo lọ?" 20 Nígbà náà ni inú àlùfáà náà dùn, òun efodu náà, àwọn òrìṣà ìdílé mìíràn àti ère fínfín náà, ó àwọn ènìyàn náà lọ. 21 Wọ́n àwọn ọmọdé wọn, àwọn ohun ̀sìn wọn àti gbogbo ohun ìní wọn síwájú, wọ́n yípadà wọ́n lọ.

22 Nígbà wọ́n ti rìn jìnnà díẹ̀ ilé Mika, àwọn ọkùnrin ó agbègbè Mika ara wọn jọ, wọ́n àwọn ará Dani . 23 wọ́n ṣe ń pariwo tẹ̀wọn lẹ́yìn, àwọn ará Dani yípadà wọ́n bi Mika , "ṣe ́ o fi pe àwọn ọkùnrin rẹ jáde láti ?"

24 Ó dáhùn , "̀yin àwọn ère mo ṣe, àti àlùfáà mi lọ. ni ó mo ? Báwo ni ̀yin ò ṣe béèrè , ṣe ́?’ "

25 Àwọn ọkùnrin Dani náà dáhùn , "ṣe wa jiyàn, tàbí àwọn oníbìínú fùfù ènìyàn kọlù yín, ìwọ àti àwọn ìdílé yóò sọ ̀yín ." 26 Àwọn ọkùnrin Dani náà ̀wọn lọ. Nígbà Mika í wọ́n lágbára púpọ̀ fún òun, ó padà ilé rẹ̀.

27 Wọ́n àwọn ohun Mika ti ṣe àti àlùfáà rẹ̀, wọ́n kọjá lọ Laiṣi, ̀dọ̀ àwọn ènìyàn ó ìbàlẹ̀ ọkàn wọ́n àlàáfíà. Wọ́n fi ojú idà kọlù wọ́n, wọ́n ìlú wọn run. 28 ẹnikẹ́ni yóò gbà wọ́n sílẹ̀ nítorí ibi wọ́n ń gbé jìnà àwọn ará Sidoni, wọn àṣepọ̀ pẹ̀ẹnikẹ́ni. Ìlú náà inú àfonífojì lẹ́bàá a Beti-Rehobu.

Àwọn ará Dani tún ìlú náà kọ́, wọ́n ń gbé inú rẹ̀. 29 Wọ́n sọ orúkọ ìlú náà Dani gẹ́gẹ́ orúkọ baba ńlá wọn Dani, ẹni wọ́n fún Israẹli: ó tilẹ̀ jẹ́ Laiṣi ni orúkọ ìlú náà tẹ́lẹ̀ . 30 Àwọn ọmọ Dani gbé àwọn ère kalẹ̀ fún ara wọn níbẹ̀; Jonatani ọmọ Gerṣomu, ọmọ Mose, àti àwọn ọmọ rẹ̀ ni àlùfáà fún àwọn ̀Dani títí di àkókò a ilẹ̀ náà ìgbèkùn. 31 Wọ́n tẹ̀síwájú láti lo àwọn ère Mika ṣe, gbogbo àkókò ilé Ọlọ́run Ṣilo.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também