Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronomi 23

Yíyọ orúkọ ènìyàn kúrò nínú orúkọ àwọn ènìyàn Olúwa

1 ẹnikẹ́ni a fọ́ kóró ẹpọ̀n nípa rírùn tàbí gígé ṣe wọ inú ìjọ Olúwa .

2 ọmọ àlè ṣe wọ ìpéjọ Olúwa, pàápàá títí ìran kẹwàá.

3 23.3-5: Ne 13.1,2. ọmọ Ammoni tàbí ọmọ Moabu, yóò wọ ìjọ Olúwa, àní títí ìran kẹwàá, ènìyàn wọn kan yóò wọ inú ìjọ ènìyàn Olúwa láéláé. 4 23.4: Nu 22.1-6.Nítorí wọn fi àkàrà àti omi pàdé e yín lójú ̀nígbà ò ń bọ̀ láti Ejibiti àti nítorí wọ́n gba ̀iṣẹ́ láti fi ́ gégùn ún Balaamu ọmọ Beori ará a Petori ti Aramu-Naharaimu. 5 23.5: Nu 23.7–24.9.Síbẹ̀síbẹ̀, Olúwa Ọlọ́run rẹ fetí Balaamu ṣùgbọ́n ó ègún ìbùkún fún , nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ fẹ́ràn rẹ. 6 Ìwọ gbọdọ̀ àlàáfíà, tàbí ire wọn níwọ̀n ìgbà o láààyè.

7 Ìwọ gbọdọ̀ kórìíra ará Edomu kan nítorí arákùnrin rẹ ni. Ìwọ gbọdọ̀ kórìíra ará Ejibiti, nítorí o gbé gẹ́gẹ́ àjèjì ilẹ̀ rẹ̀. 8 Ìran kẹta àwọn ọmọ a fún wọn wọ ìpéjọ Olúwa.

Ìwà àìmọ́ nínú àgọ́

9 Nígbà o ti àwọn ̀rẹ, pa gbogbo ohun àìmọ́ kúrò. 10 ̀kan nínú àwọn ọkùnrin rẹ jẹ́ aláìmọ́ nítorí ìtújáde ó , o láti jáde kúrò nínú àgọ́, o ṣe wọ inú àgọ́. 11 Ṣùgbọ́n nígbà ó di ìrọ̀lẹ́ o láti wẹ ara rẹ, àti àṣálẹ́ o padà sínú àgọ́.

12 Sàmì ibìkan lóde àgọ́, níbi o máa lọ láti dẹ ara rẹ lára. 13 ìwọ ó ìwalẹ̀ kan pẹ̀ohun ìjà rẹ; yóò ṣe, nígbà ìwọ yóò gbọnṣẹ̀ lẹ́yìn ibùdó, ìwọ ó ìwalẹ̀, ìwọ ó yípadà, o bo ohun ó jáde láara rẹ. 14 Nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ ń rìn láàrín àgọ́ láti dáàbò ́ àti láti fi àwọn ̀à rẹ lọ́wọ́. Àgọ́ rẹ láti jẹ́ mímọ́, nítorí ó ba à ohun àìtọ́ láàrín yín ó yípadà kúrò lọ́dọ̀ yín.

Onírúurú òfin

15 ẹrú kan ti gba ààbò lọ́dọ̀ rẹ, ṣe fi ̀rẹ̀ lọ́wọ́. 16 Jẹ́ ó máa gbé láàrín rẹ níbikíbi ó fẹ́ àti èyíkéyìí ìlú ó . ṣe ni í lára.

17 ọkùnrin tàbí obìnrin Israẹli ṣe padà di alágbèrè ojúbọ òrìṣà. 18 Ìwọ gbọdọ̀ owó iṣẹ́ panṣágà obìnrin tàbí ọkùnrin ilé Olúwa Ọlọ́run rẹ láti fi san ̀jẹ́ kankan; nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ kórìíra àwọn méjèèjì.

19 23.19: El 22.26; Le 25.35-37. Ìwọ gbọdọ̀ ka èlé arákùnrin rẹ lọ́rùn, bóyá lórí owó tàbí oúnjẹ tàbí ohunkóhun mìíràn ó èlé . 20 Ìwọ ka èlé àlejò lọ́rùn, ṣùgbọ́n í ṣe arákùnrin ọmọ Israẹli, nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ bùkún nínú ohun gbogbo o dáwọ́ilẹ̀ ò ń wọ̀ lọ láti .

21 23.21-23: Nu 30.2-16. o jẹ́ ̀jẹ́ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ, ṣe lọ́ra láti san án, nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò béèrè rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ, o máa jẹ̀bi ̀ṣẹ̀. 22 Ṣùgbọ́n o fàsẹ́yìn láti jẹ́ ̀jẹ́, o jẹ̀bi. 23 i dájú o ṣe ohunkóhun o ti ètè rẹ jáde, nítorí ìwọ fi tinútinú rẹ jẹ́ ̀jẹ́ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀ẹnu ara rẹ.

24 ìwọ wọ inú ọgbà àjàrà aládùúgbò rẹ, o jẹ gbogbo èso àjàrà o fẹ́, ṣùgbọ́n ṣe fi nǹkan kan sínú agbọ̀n rẹ. 25 ìwọ wọ inú oko ọkà aládùúgbò rẹ, o fi ọwọ́ rẹ ya síírí rẹ̀, ṣùgbọ́n o gbọdọ̀ ki dòjé bọ ọkà ó dúró.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também