Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronomi 27

Pẹpẹ orí òkè Ebali

1 Mose àti àwọn àgbàgbà Israẹli pàṣẹ fún àwọn ènìyàn , "Pa gbogbo àṣẹ mo fún lónìí mọ́. 2 Nígbà o ti kọjá a Jordani inú ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ ń fún , gbé kalẹ̀ lára àwọn òkúta ńlá àti aṣọ ìlekè rẹ pẹ̀ẹfun. 3 ìwọ ó kọ gbogbo ̀rọ̀ òfin yìí sára wọn nígbà ìwọ ti ń rékọjá láti wọ ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ ń fún , ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti oyin, gẹ́gẹ́ Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín ti ṣèlérí fún . 4 Àti nígbà o ti kọjá a Jordani, o gbé òkúta yìí kalẹ̀ sórí i Ebali, mo ti pa à láṣẹ fún lónìí, o wọ̀ wọ́n pẹ̀ẹfun. 5 Kọ́ pẹpẹ síbẹ̀ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ, pẹpẹ òkúta. ṣe lo ohun èlò irin lórí wọn. 6 ìwọ ó mọ pẹpẹ pẹ̀òkúta àìgbẹ́ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ, ìwọ ó máa ẹbọ sísun ni orí rẹ̀ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ. 7 ẹbọ àlàáfíà níbẹ̀ o jẹ wọ́n, o yọ̀ níwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ. 8 o kọ gbogbo àwọn ̀rọ̀ òfin yìí ketekete sórí òkúta ó ti gbé kalẹ̀."

Ègún orí òkè Ebali

9 Nígbà náà ni Mose àti àwọn àlùfáà wọ́n jẹ́ ọmọ Lefi, sọ fún Israẹli , "dákẹ́ ̀yin Israẹli, fetísílẹ̀! O ti di ènìyàn Olúwa Ọlọ́run rẹ báyìí. 10 Gbọ́rọ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ o tẹ̀àṣẹ àti òfin rẹ̀ mo ń fi fún lónìí."

11 ọjọ́ kan náà Mose pàṣẹ fún àwọn ènìyàn .

12 Nígbà ìwọ ti kọjá a Jordani, àwọn ̀yìí yóò dúró lórí òkè Gerisimu láti súre fún àwọn ènìyàn: Simeoni, Lefi, Juda, Isakari, Josẹfu àti Benjamini. 13 Àwọn ̀yìí yóò dúró lórí òkè Ebali láti ègún: Reubeni, Gadi, àti Aṣeri, àti Sebuluni, Dani, àti Naftali.

14 Àwọn ̀Lefi yóò gbogbo ènìyàn Israẹli ohùn òkè:

15 27.15: Ek 20.4,23; 34.17; Le 19.4; 26.1; De 4.16,23,25; 5.8; 7.25. "Ègún ni fún ọkùnrin náà ó fín ère tàbí gbẹ́ òrìṣà ohun ó jẹ́ ìríra níwájú Olúwa, iṣẹ́ ọwọ́ oníṣọ̀ó gbé kalẹ̀ ìkọ̀kọ̀."

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò , "Àmín!"

16 27.16: Ek 20.12; 21.15,17; Le 20.9; De 5.16; 21.18-21. "Ègún ni fún ọkùnrin náà ó dójútì baba tàbí ìyá rẹ̀."

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò , "Àmín!"

17 "Ègún ni fún ọkùnrin náà ó òkúta ààlà aládùúgbò o rẹ̀."

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò , "Àmín!"

18 27.18: Le 19.14. "Ègún ni fún ọkùnrin náà ó ṣi afọ́lọ́ojú ̀."

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò , "Àmín!"

19 27.19: Ek 22.21-24; 23.9; Le 19.33,34; De 24.17,18. "Ègún ni fún ọkùnrin náà ó ìdájọ́ po fún àlejò, aláìní baba tàbí opó."

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò , "Àmín!"

20 27.20: Le 18.8; 20.11; De 22.30. "Ègún ni fún ọkùnrin náà ó dùbúlẹ̀ pẹ̀ìyàwó baba rẹ̀, nítorí ó ti dójúti ibùsùn baba rẹ̀."

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò , "Àmín!"

21 27.21: Ek 22.19; Le 18.23; 20.15. "Ègún ni fún ọkùnrin náà ó ìbálòpọ̀ pẹ̀ẹranko."

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò , "Àmín!"

22 "Ègún ni fún ọkùnrin náà ó dùbúlẹ̀ pẹ̀arábìnrin rẹ̀, ọmọbìnrin baba rẹ̀ tàbí ọmọbìnrin ìyá rẹ̀."

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò , "Àmín!"

23 27.23: Le 18.17; 20.14. "Ègún ni fún ọkùnrin náà ó dùbúlẹ̀ pẹ̀ìyá ìyàwó o rẹ̀."

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò , "Àmín!"

24 "Ègún ni fún ọkùnrin náà ó pa aládùúgbò rẹ̀ ìkọ̀kọ̀."

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò , "Àmín!"

25 "Ègún ni fún ọkùnrin náà ó gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ láti pa ènìyàn láìjẹ̀bi."

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò , "Àmín!"

26 27.26: Ga 3.10. "Ègún ni fún ọkùnrin náà gbé ̀rọ̀ òfin yìí nípa ṣíṣe wọ́n."

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò , "Àmín!"

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também