Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronomi 31

Joṣua rọ́Mose

1 Nígbà náà ni Mose jáde ó sọ àwọn ̀rọ̀ wọ̀nyí gbogbo Israẹli , 2 "Mo jẹ́ ọmọ ọgọ́ọdún báyìí àti èmi ni darí i yín mọ́. Olúwa ti sọ fún mi , Ìwọ kọjá Jordani.3 Olúwa Ọlọ́run rẹ fúnra rẹ̀ ni yóò rékọjá fún . Yóò pa àwọn orílẹ̀-èdè yìí run níwájú rẹ, ìwọ yóò ìní ilẹ̀ wọn, Joṣua náà yóò rékọjá fún , Olúwa ti sọ. 4 Olúwa yóò ṣe fún wọn ohun ó ti ṣe Sihoni àti Ogu ọba Amori, ó parun pẹ̀ilẹ̀ wọn. 5 Olúwa yóò fi wọ́n fún , o ṣe wọn gbogbo èyí mo ti pàṣẹ fún . 6 31.6,8: Hb 13.5.Jẹ́ alágbára o ìgboyà. ṣe bẹ̀tàbí jáyà nítorí i wọn, nítorí Olúwa Ọlọ́run rẹ ń lọ pẹ̀rẹ, Òun fi ́ sílẹ̀ tàbí kọ̀ ́ sílẹ̀."

7 Nígbà náà ni Mose pe Joṣua ó fún un níwájú gbogbo Israẹli , "Jẹ́ alágbára àti onígboyà, nítorí o láti lọ pẹ̀àwọn ènìyàn wọ̀nyí ilẹ̀ Olúwa búra fún àwọn baba ńlá a wọn láti fún wọn, o pín ilẹ̀ náà láàrín wọn ogún wọn. 8 Olúwa fúnra rẹ̀ ń lọ níwájú rẹ yóò pẹ̀rẹ; fi ́ sílẹ̀ tàbí kọ̀ ́ sílẹ̀. ṣe bẹ̀ṣe fòyà."

Kíka òfin

9 Nígbà náà ni Mose kọ òfin yìí kalẹ̀ ó fi fún àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi, ń gbé àpótí ̀Olúwa, àti fún gbogbo àwọn àgbàgbà Israẹli. 10 Nígbà náà ni Mose pàṣẹ fún wọn, "òpin ọdún méje méje, àkókò ọdún ìdásílẹ̀, nígbà àjọ àwọn àgọ́. 11 Nígbà gbogbo Israẹli láti fi ara hàn níwájú Olúwa Ọlọ́run wa ibi yóò yàn, ìwọ yóò ka òfin yìí níwájú wọn etí ìgbọ́ wọn. 12 Pe àwọn ènìyàn jọ àwọn ọkùnrin, àwọn obìnrin àti àwọn àjèjì ń gbé àwọn ìlú u yín wọn fetí i wọn kọ́ láti bẹ̀Olúwa Ọlọ́run rẹ wọn rọra tẹ̀gbogbo ̀rọ̀ òfin yìí. 13 Àwọn ọmọ wọn wọn mọ òfin yìí, gbọdọ̀ gbọ́ wọn kọ́ láti bẹ̀Olúwa Ọlọ́run rẹ níwọ̀n ìgbà o ń gbé ilẹ̀ ò ń kọjá la Jordani lọ láti ni."

Ìsọtẹ́lẹ̀ Israẹli ọlọ̀tẹ̀

14 Olúwa sọ fún Mose , "Ọjọ́ ikú rẹ ti súnmọ́ etílé báyìí. Pe Joṣua fi ara yín hàn nínú àgọ́ àjọ, níbi èmi yóò ti fi àṣẹ fún un." Nígbà náà ni Mose àti Joṣua , wọ́n fi ara wọn hàn níbi àgọ́ àjọ.

15 Nígbà náà ni Olúwa farahàn níbi àgọ́ ̀wọ́ àwọsánmọ̀, àwọsánmọ̀ náà dúró sókè ẹnu-ọ̀àgọ́. 16 Olúwa sọ fún Mose , "Ìwọ ń lọ sinmi pẹ̀àwọn baba à rẹ, àwọn wọ̀nyí yóò ṣe àgbèrè ara wọn ọlọ́run àjèjì ilẹ̀ wọn ń wọ̀ lọ láìpẹ́. Wọn yóò kọ̀ sílẹ̀ wọn yóò da májẹ̀mo wọn . 17 ọjọ́ náà ni èmi yóò bínú wọn èmi yóò kọ̀ wọ́n sílẹ̀; èmi yóò pa ojú mi mọ́ kúrò fún wọn, wọn yóò parun. ̀pọ̀lọpọ̀ àjálù àti ìṣòro yóò sórí wọn, àti ọjọ́ náà ni wọn yóò béèrè , Ǹjẹ́ ìpọ́njú wọ̀nyí sórí i wa nítorí Ọlọ́run wa pẹ̀u wa?18 Èmi yóò pa ojú mi mọ́ dájúdájú ọjọ́ náà nítorí i gbogbo ìwà búburú wọn yíyípadà ọlọ́run mìíràn.

19 "báyìí kọ ́ kalẹ̀ fúnra à rẹ orin yìí o kọ ́ Israẹli o jẹ́ wọn kọ ́ ó jẹ́ ̀ì mi wọn. 20 Nígbà mo ti wọn ilẹ̀ ń sàn fún wàrà àti fún oyin, ilẹ̀ mo ti ṣe ìlérí ìbúra fún àwọn baba ńlá wọn, àti nígbà wọ́n jẹ, ó tẹ́ wọn lọ́rùn, wọ́n gbilẹ̀, wọn yóò padà ọlọ́run mìíràn wọn yóò sìn wọ́n, wọn yóò kọ̀ sílẹ̀, wọn yóò da májẹ̀mi. 21 Àti nígbà ̀pọ̀lọpọ̀ ìpọ́njú àti ìṣòro sórí i wọn, orin yìí yóò jẹ́ ̀wọn, nítorí di ìgbàgbé fún àwọn ọmọ wọn. Mo mọ̀ ohun wọ́n inú dídùn láti ṣe, pàápàá èmi wọn ilẹ̀ mo ṣe ìlérí fún wọn lórí ìbúra." 22 Nígbà náà ni Mose kọ orin yìí kalẹ̀ ọjọ́ náà ó kọ ́ Israẹli.

23 Olúwa fún Joṣua ọmọ Nuni àṣẹ yìí: "Jẹ́ alágbára àti onígboyà, nítorí ìwọ yóò Israẹli ilẹ̀ mo ṣèlérí fún wọn lórí ìbúra, èmi fúnra à mi yóò pẹ̀rẹ."

24 Lẹ́yìn ìgbà Mose ti parí i kíkọ ̀rọ̀ òfin yìí sínú ìwé láti ìbẹ̀rẹ̀ òpin, 25 ó fi àṣẹ yìí fún àwọn ọmọ Lefi wọ́n ń gbé àpótí ̀Olúwa: 26 "Gba ìwé òfin yìí o fi ̀gbẹ́ àpótí ̀Olúwa Ọlọ́run rẹ. Níbẹ̀ ni yóò ̀. 27 Nítorí mo mọ irú ọlọ̀tẹ̀ àti ọlọ́rùn líle jẹ́. o ṣe ọlọ̀tẹ̀ Olúwa nígbà mo pàpà láyé pẹ̀yín, báwo ó ti ṣe ọlọ̀tẹ̀ nígbà mo tán! 28 péjọpọ̀ síwájú mi gbogbo àgbà ̀yín àti àwọn aláṣẹ yín, èmi sọ àwọn ̀rọ̀ wọ̀nyí etí ìgbọ́ ́ wọn. 29 Nítorí mo mọ̀ lẹ́yìn ikú mi, ó dájú ìwọ yóò padà di ìbàjẹ́ pátápátá, ó yípadà kúrò ̀mo ti pàṣẹ fún un yín. ọjọ́ ń bọ̀, ìpọ́njú yóò sọ̀kalẹ̀ sórí i yín nítorí ̀yin yóò ṣe búburú níwájú Olúwa ó u bínú nípa ohun ọwọ́ yín ti ṣe."

Orin Mose

30 Mose ka ̀rọ̀ inú orin yìí láti ìbẹ̀rẹ̀ títí òpin etí ìgbọ́ gbogbo ìjọ Israẹli:

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também