Pular para o conteúdo
Publicidade

Deuteronomi 26

Àkọ́so àti ìdámẹ́wàá

1 26.1-11: El 22.29; 23.19; 34.26; Nu 18.12,13. Nígbà ìwọ wọ ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ ń fi fún gẹ́gẹ́ ohun ìní ìwọ ti jogún, ìwọ ti ń gbé níbẹ̀, 2 díẹ̀ nínú ohun o pèsè láti inú erùpẹ̀ ilẹ̀ náà Olúwa Ọlọ́run rẹ ń fi fún , wọn sínú agbọ̀n. Nígbà náà o lọ ibi Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò yàn gẹ́gẹ́ ibi orúkọ rẹ̀ yóò máa gbé. 3 o sọ fun àlùfáà ó ibi iṣẹ́ àsìkò náà, , "Mo sọ ́ di mọ̀ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ mo ti ilẹ̀ Olúwa búra fún àwọn baba wa." 4 Àlùfáà yóò gbé agbọ̀n náà kúrò ọwọ́ rẹ, yóò gbé e kalẹ̀ níwájú pẹpẹ Olúwa Ọlọ́run rẹ. 5 Nígbà náà ni ìwọ yóò sọ iwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ , "Baba mi jẹ́ alárìnkiri ará Aramu, ó sọ̀kalẹ̀ Ejibiti pẹ̀ènìyàn díẹ̀, ó ń gbé níbẹ̀, ó di orílẹ̀-èdè olókìkí, alágbára, ó kún fún ̀pọ̀ ènìyàn. 6 Ṣùgbọ́n àwọn ará Ejibiti ṣe àìdára wa, wọ́n jẹ , wọ́n fún wa iṣẹ́ líle ṣe. 7 Nígbà náà ni a kégbe pe Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wa, Olúwa gbọ́ ohùn wa, ó ìrora, làálàá àti ìnira wa. 8 Nígbà náà ni Olúwa wa jáde láti Ejibiti pẹ̀ọwọ́ agbára àti apá nínà, pẹ̀̀ńlá àti iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu. 9 Ó wa síbí, ó fún wa ilẹ̀ yìí, ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti oyin; 10 àti báyìí, mo àkọ́so ilẹ̀ ìwọ Olúwa ti fún mi ." Ìwọ yóò gbé agbọ̀n náà síwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ, o wólẹ̀ níwájú u rẹ̀. 11 Ìwọ àti àwọn ọmọ Lefi àti àjèjì láàrín yín yóò máa yọ̀ nínú gbogbo oore Olúwa ti fi fún àti fún àwọn ará ilé rẹ.

12 Nígbà ìwọ ṣetán láti ya ìdámẹ́wàá gbogbo ohun o ti jáde ọdún kẹta sọ́tọ̀ apá kan. Ọdún ìdámẹ́wàá, ìwọ yóò fi fún ọmọ Lefi, àjèjì, aláìní baba àti opó, wọn ó jẹ àwọn ìlú rẹ, wọn . 13 Nígbà náà o fún Olúwa Ọlọ́run rẹ , "Èmi ti ohun mímọ́ kúrò nínú ilé mi, èmi ti fi fún àwọn Lefi, àwọn àjèjì, àwọn aláìní baba àti àwọn opó, gẹ́gẹ́ ohun gbogbo ìwọ ti pàṣẹ. Èmi yípadà kúrò nínú àṣẹ rẹ bẹ́̀ ni èmi gbàgbé ̀kankan nínú wọn. 14 Èmi jẹ lára ohun mímọ́ ìgbà mo ń ṣọ̀fọ̀, bẹ́̀ ni èmi mu nínú wọn ìgbà mo àìmọ́, bẹ́̀ ni èmi fi nínú wọn fún òkú. Èmi ti ṣe ìgbọ́ràn Olúwa Ọlọ́run mi, èmi ti ṣe gbogbo ohun ó pàṣẹ fún mi. 15 Wo ilẹ̀ láti ̀run , ibùgbé mímọ́ rẹ, o bùkún fún àwọn ènìyàn Israẹli, àti fún ilẹ̀ náà ìwọ ti fi fún wa, ìwọ ti búra fún àwọn baba ńlá wa, ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti fún oyin."

Tẹ̀àṣẹ Olúwa

16 Olúwa Ọlọ́run rẹ pàṣẹ fún òní láti máa tẹ̀àwọn ìlànà àti òfin, o máa ṣe wọ́n pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ àti gbogbo àyà rẹ. 17 Ìwọ jẹ́wọ́ Olúwa òní Olúwa ni Ọlọ́run rẹ, àti ìwọ yóò máa rìn ̀rẹ̀ gbogbo, àti ìwọ yóò máa pa ìlànà rẹ̀, àṣẹ rẹ̀ àti òfin rẹ̀ mọ́, àti ìwọ yóò máa ṣe ìgbọ́ràn i. 18 òní ni Olúwa jẹ́wọ́ rẹ ìwọ ni ènìyàn òun, ilé ìṣúra rẹ̀ gẹ́gẹ́ òun ti ṣe ìlérí, àti ìwọ yóò máa pa gbogbo àṣẹ rẹ̀ mọ́. 19 Òun jẹ́wọ́ , òun yóò gbé sókè ju gbogbo orílẹ̀-èdè òun ti lọ, ìyìn, òkìkí àti ọlá; ìwọ ó le jẹ́ ènìyàn mímọ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ gẹ́gẹ́ òun ti ṣe ìlérí.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também