Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 34

Ààlà ti Kenaani

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 "Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli, o sọ fún wọn , wọ Kenaani, ilẹ̀ a ó fi fún yín, gẹ́gẹ́ ogún yín yóò ààlà wọn :

3 34.3-5: Jo 15.1-4. " Ìhà gúúsù yín yóò bọ́ ara aginjù Sini lẹ́bàá Edomu, àti ìlà-oòrùn, ààlà ìhà gúúsù yóò bẹ̀rẹ̀ láti òpin Òkun Iyọ̀, 4 kọjá lọ gúúsù Akrabbimu, tẹ̀síwájú lọ si Sini, bọ́ si gúúsù Kadeṣi-Barnea, o Hasari-Addari, o kọjá Asmoni. 5 òpin ilẹ̀ rẹ̀ ó yíká láti Asmoni lọ odò Ejibiti, Òkun Ńlá ni yóò jẹ òpin rẹ.

6 Ìhà ìwọ̀-oòrùn yín yóò jẹ́ òpin lórí Òkun Ńlá. Èyí yóò jẹ́ ààlà yín lórí ìhà ìwọ̀-oòrùn.

7 Fún ààlà ìhà àríwá, fa ìlà láti Òkun Ńlá lọ orí òkè Hori, 8 àti láti orí òkè Hori Lebo-Hamati. Nígbà náà ààlà náà yóò lọ Sedadi, 9 tẹ̀síwájú lọ Sifroni, o pín si Hasari-Enani, èyí yóò jẹ́ ààlà tìrẹ ìhà àríwá.

10 sàmì ilẹ̀ tiyín ìhà ìlà-oòrùn láti Hasari-Enani lọ Ṣefamu. 11 Ààlà náà yóò ti Ṣefamu sọ̀kalẹ̀ lọ Ribla ìhà ìlà-oòrùn Aini, o sọ̀kalẹ̀ lọ ìhà Òkun Kinnereti ìhà ìlà-oòrùn. 12 Nígbà náà, ààlà náà yóò sọ̀kalẹ̀ lọ apá Jordani, yóò dópin nínú Òkun Iyọ̀.

" Èyí yóò jẹ́ ilẹ̀ yín, pẹ̀ààlà tirẹ̀ gbogbo ̀.’ "

13 34.13-15: Jo 14.1-5. Mose pa á láṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli , "Yan ilẹ̀ yìí pẹ̀kèké gẹ́gẹ́ ìní ogún: Olúwa ti pàṣẹ láti fi fún ̀mẹ́sàn-án, àti ààbọ̀. 14 Nítorí ará ilẹ̀ ̀ti Reubeni, ̀Gadi àti ̀ààbọ̀ ti Manase ti gba ogún tiwọn. 15 ̀méjèèjì àti ààbọ̀ yìí ti gba ogún tiwọn ìhà ìhín Jordani létí i Jeriko, ìhà ìlà-oòrùn, ìdojúkọ Jordani."

16 Olúwa sọ fún Mose , 17 "Èyí ni orúkọ àwọn ọkùnrin náà yóò pín ilẹ̀, náà fún yín gẹ́gẹ́ ogún: Eleasari àlùfáà àti Joṣua ọmọ Nuni. 18 o yan olórí kan nínú ̀kọ̀̀kan láti pín ilẹ̀ náà.

19 "Èyí ni orúkọ wọn:

"Kalebu ọmọ Jefunne, láti ̀Juda;

20 Ṣemueli ọmọ Ammihudu, láti ̀Simeoni;

21 Elidadi ọmọ Kisloni, láti ̀Benjamini;

22 Bukki ọmọ Jogli, láti ̀olórí àwọn ọmọ Dani;

23 Hannieli ọmọ Efodu, láti ̀Manase, olórí àwọn ọmọ Josẹfu,

24 Kemueli ọmọ Ṣiftani, olórí ̀àwọn ọmọ, Efraimu, ọmọ Josẹfu;

25 Elisafani ọmọ Parnaki, olórí ̀àwọn ọmọ Sebuluni;

26 Paltieli ọmọ Assani, olórí ̀àwọn ọmọ Isakari;

27 Ahihudu ọmọ Ṣelomi, olórí ̀àwọn ọmọ Aṣeri;

28 Pedaheli ọmọ Ammihudu, olórí ̀àwọn ọmọ Naftali."

29 Èyí ni àwọn ẹni Olúwa yàn láti pín ogún náà fún àwọn ọmọ Israẹli ilẹ̀ Kenaani.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também