Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 14

Àwọn ọmọ Israẹli kọ̀ láti lọ Kenaani

1 Gbogbo ìjọ ènìyàn gbóhùn sókè, wọ́n sọkún òru ọjọ́ náà. 2 Gbogbo ọmọ Israẹli kùn Mose àti Aaroni, gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli fún wọn , "Àwa ìbá kúkú ti ilẹ̀ Ejibiti. Tàbí a kúkú sínú aginjù yìí. 3 14.3: Ap 7.39.Olúwa fi wa ilẹ̀ yìí láti fi idà pa ? Àwọn ìyàwó wa, àwọn ọmọ wa yóò di ìjẹ. Ǹjẹ́ wa, í dára fún wa a padà Ejibiti?" 4 Wọ́n sọ fún ara wọn , "jẹ́ á yan olórí á padà Ejibiti."

5 Nígbà náà ni Mose àti Aaroni dojúbolẹ̀ níwájú gbogbo ìjọ ọmọ Israẹli. 6 Joṣua ọmọ Nuni àti Kalebu ọmọ Jefunne, wọ́n lára àwọn to lọ yẹ ilẹ̀ fa aṣọ wọn ya. 7 Wọ́n sọ fún gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli , "Ilẹ̀ a kọjá láti yẹ̀ náà jẹ́ ilẹ̀ ó dára lọ́pọ̀lọ́pọ̀. 8 inú Olúwa dùn wa, yóò wa ilẹ̀ náà, ilẹ̀ ń sàn fún wàrà àti fún oyin, yóò fún wa ilẹ̀ náà. 9 Ṣùgbọ́n ṣe ṣọ̀tẹ̀ Olúwa. bẹ̀àwọn ènìyàn ìlú náà, nítorí a ó gbé wọn , ààbò wọn ti fi wọ́n sílẹ̀, Olúwa pẹ̀àwa, ṣe bẹ̀wọn."

10 Ṣùgbọ́n gbogbo ìjọ ènìyàn ń sọ àwọn yóò sọ wọ́n lókùúta pa. Nígbà náà ni ògo Olúwa fi ara hàn àgọ́ ìpàdé níwájú àwọn ọmọ Israẹli.

Mose bẹ̀bẹ̀ fún àwọn ènìyàn

11 14.11-25: Ek 32.9-14,31-35. Olúwa sọ fún Mose , "Fún ìgbà wo ni àwọn ènìyàn yìí yóò ti kẹ́gàn mi ? Báwo ni yóò ti pẹ́ wọ́n ó fi kọ̀ jálẹ̀ láti gbà gbọ́, pẹ̀gbogbo iṣẹ́ àmì mo ṣe láàrín wọn? 12 Èmi ó kọlù wọ́n pẹ̀àjàkálẹ̀-ààrùn, èmi ó gba ogún wọn lọ́wọ́ wọn, èmi ó pa wọ́n run ṣùgbọ́n èmi ó sọ ́ di orílẹ̀-èdè ńlá lágbára wọ́n lọ."

13 Ṣùgbọ́n Mose sọ fún Olúwa , "Nígbà náà ni àwọn ará Ejibiti yóò gbọ́! Nítorí nípa agbára rẹ ni ìwọ fi àwọn ènìyàn wọ̀nyí jáde kúrò láàrín wọn. 14 Wọ́n ó sọ fún àwọn olùgbé ilẹ̀ yìí. Àwọn ti mọ̀ tẹ́lẹ̀ ìwọ Olúwa láàrín àwọn ènìyàn wọ̀nyí àti wọ́n ìwọ, Olúwa, ojúkojú, àti ìkùùkuu àwọsánmọ̀ rẹ dúró lórí wọn, bẹ́̀ ni ìwọ ń lọ níwájú wọn pẹ̀ìkùùkuu àwọsánmọ̀ ̀sán àti pẹ̀̀wọ́n iná òru. 15 ìwọ pa àwọn ènìyàn wọ̀nyí lẹ́̀kan ṣoṣo, àwọn orílẹ̀-èdè gbọ́ ìròyìn yìí nípa rẹ yóò , 16 Nítorí Olúwa le è àwọn ènìyàn wọ̀nyí ilẹ̀ ó ṣèlérí fún wọn; torí èyí ṣe pa wọ́n sínú aginjù yìí.

17 "Báyìí, mo gbàdúrà, jẹ́ agbára Olúwa tóbi gẹ́gẹ́ ìwọ ti sọ , 18 Olúwa lọ́ra láti bínú, ó pọ̀ ìfẹ́ dúró ṣinṣin, ń dárí ̀ṣẹ̀ àti ìrékọjá . Bẹ́̀ ni í jẹ́ ẹlẹ́bi lọ láìjìyà; ń fi ìyà ̀ṣẹ̀ baba jẹ ọmọ títí ìran kẹta àti ìran kẹrin.19 Dárí ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn yìí wọ́n, mo bẹ̀ ́, gẹ́gẹ́ ìfẹ́ ńlá rẹ, o ti ṣe ń dárí ̀ṣẹ̀ wọn wọ́n láti ìgbà o ti wọn kúrò Ejibiti di ìsin yìí."

20 Olúwa dáhùn , "Mo ti dáríjì wọ́n gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ rẹ. 21 Ṣùgbọ́n nítòótọ́ mo ti láààyè, gbogbo ayé yóò kún fún ògo Olúwa. 22 14.22,23: Hb 3.18.̀kan nínú àwọn ènìyàn ògo mi àti àwọn iṣẹ́ àmì mo ṣe ilẹ̀ Ejibiti àti nínú aginjù ṣùgbọ́n wọ́n ṣe àìgbọ́ràn mi, wọn dán mi ìgbà mẹ́wàá yìí, 23 ̀kan nínú wọn ilẹ̀ náà mo ṣe ìlérí ìbúra láti fún baba ńlá wọn. ̀kan nínú àwọn kẹ́gàn mi yóò ilẹ̀ náà. 24 Ṣùgbọ́n nítorí Kalebu ìránṣẹ́ mi ̀̀tọ̀, ó tún tẹ̀mi tọkàntọkàn, èmi ó mu ilẹ̀ náà lọ yẹ̀ , irú àwọn ọmọ rẹ̀ yóò jogún rẹ̀. 25 Níwọ́n ìgbà àwọn ará Amaleki àti àwọn ará Kenaani ń gbé àfonífojì, yípadà lọ́la dojúkọ aginjù lọ́Òkun Pupa."

26 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni , 27 "Báwo ni yóò ti pẹ́ àwọn ìjọ ènìyàn búburú yìí yóò fi máa kùn mi? Mo ti gbọ́ kíkùn àwọn ọmọ Israẹli ń kùn mi. 28 Sọ fún wọn, mo ti láààyè nítòótọ́ ni Olúwa , gẹ́gẹ́ ohun létí mi ni èmi ó ṣe fún un yín. 29 14.29: Hb 3.17.Nínú aginjù yìí ni ó , gbogbo ̀yin kùn láti ọmọ ogún ọdún ó àní gbogbo ̀yin a . 30 ̀kan nínú yín í ilẹ̀ mo búra nípa ìgbọ́wọ́sókè láti fi ṣe ibùgbé yín, ṣe Kalebu ọmọ Jefunne àti Joṣua ọmọ Nuni. 31 Ṣùgbọ́n ti àwọn ọmọ yín wọn ó di ìjẹ, àwọn ni n ó bẹ̀ láti gbádùn ilẹ̀ kọ̀sílẹ̀. 32 Ṣùgbọ́n ̀yin, òkú yín yóò ṣubú aginjù yìí. 33 14.33: Ap 7.36.Àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ yín yóò máa rin kiri nínú aginjù fun ogójì ọdún wọn ó máa jìyà nítorí àìnígbàgbọ́ yín, títí ọkàn gbogbo yín yóò fi ṣòfò tán aginjù. 34 Fún ogójì ọdún èyí jẹ́ ọdún kan fún ọjọ́ kọ̀̀kan nínú ogójì ọjọ́ fi yẹ ilẹ̀ náà ̀yin ó jìyà fún ̀ṣẹ̀ yín, ó mọ ó ti láti lòdì mi. 35 Èmi, Olúwa, lo sọ bẹ́̀; Èmi ó ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí ìjọ ènìyàn búburú yìí wọ́n ra wọn jọ lòdì mi. Nínú aginjù yìí ni òpin yóò wọn, ibẹ̀ ni wọn yóò ."

36 Àwọn ọkùnrin Mose rán láti yẹ ilẹ̀ , wọ́n gbogbo ìjọ kùn i nípa ìròyìn búburú wọ́n nípa ilẹ̀ náà; 37 Olúwa kọlu àwọn ọkùnrin ìròyìn búburú nípa ilẹ̀ náà, àjàkálẹ̀-ààrùn pa wọ́n níwájú Olúwa. 38 Nínú gbogbo àwọn lọ yẹ ilẹ̀ náà , Joṣua ọmọ Nuni àti Kalebu ọmọ Jefunne é.

39 Nígbà Mose sọ gbogbo ̀rọ̀ yìí fún àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sọkún gidigidi. 40 Wọ́n dìde àárọ̀ ọjọ́ kejì wọ́n gòkè lọ ìlú orí òkè, wọ́n , "Àwa ti ṣẹ̀, àwa yóò lọ ibi Olúwa ṣèlérí fún wa."

41 Mose wọn lóhùn , "fi ṣẹ̀ òfin Olúwa? Èyí le yọrí rere! 42 ṣe gòkè lọ nítorí Olúwa láàrín yín. Ki á ba à yín bolẹ̀ níwájú àwọn ̀yín. 43 Nítorí àwọn ará Amaleki àti àwọn ará Kenaani ń bẹ níwájú yín, ̀yin yóò ti ipa idà ṣubú. Nítorí , ti kúrò ̀Olúwa, Olúwa í pẹ̀yín."

44 Síbẹ̀síbẹ̀, pẹ̀àìfarabalẹ̀ wọn, wọ́n gòkè lọ sórí òkè náà, láìjẹ́ àpótí ̀Olúwa tàbí Mose kúrò nínú ibùdó. 45 Àwọn ará Amaleki àti àwọn ará Kenaani ń gbé lórí òkè sọ̀kalẹ̀ tọ̀ wọ́n, wọ́n wọn , wọ́n wọn títí Horma.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também