Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 4

Àwọn ọmọ Kohati

1 4.1-33: Nu 1.50-53; 3.5-8,21-37; 8.19; 18.3,4,23. Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni , 2 "Ka iye àwọn ọmọ Kohati láàrín àwọn ọmọ Lefi nípa ilé baba wọn àti ìdílé wọn. 3 Ka gbogbo ọkùnrin láti ọmọ ọgbọ̀n ọdún títí àádọ́ta ọdún gbogbo àwọn ń ṣiṣẹ́ nínú àgọ́ ìpàdé.

4 "Wọ̀nyí ni iṣẹ́ ìsìn àwọn ọmọ Kohati nínú àgọ́ àjọ, láti tọ́àwọn ohun èlò mímọ́ jùlọ. 5 Nígbà àgọ́ yóò tẹ̀síwájú, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò wọ inú rẹ̀, wọn yóò aṣọ ìbòrí rẹ̀, wọn yóò fi bo àpótí ̀. 6 Wọn yóò fi awọ ewúrẹ́ ó, lórí awọ ewúrẹ́ yìí ni wọn ó tẹ̀ bọ ààyè rẹ̀.

7 "Lórí tábìlì àkàrà ìfihàn ni wọn ó na aṣọ aláró kan , wọn ó fi àwopọ̀kọ́ sórí rẹ̀, àti ṣíbí àti àwokòtò àti ìgò fún ọrẹ ohun mímu; àti àkàrà ìgbà gbogbo ó lórí rẹ̀. 8 Lórí gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni wọn yóò da, wọn ó tún fi awọ ewúrẹ́ ó, wọn ó fi òpó rẹ̀ bọ ààyè rẹ̀.

9 "wọn ó aṣọ aláwọ̀ aláró kan, wọn ó fi bo ̀fìtílà àti fìtílà rẹ̀, àti alumagaji rẹ̀, àti àwo alumagaji rẹ̀, àti gbogbo ohun èlò òróró rẹ̀, èyí wọ́n fi ń ṣe iṣẹ́ rẹ̀. 10 wọn ó fi awọ ẹran fìtílà àti gbogbo ohun èlò rẹ, wọn ó gbé e orí férémù wọn yóò fi gbé e.

11 "orí pẹpẹ wúrà ni wọn ó tẹ́ aṣọ aláró kan , wọn yóò fi awọ seali ó, wọ́n fi òpó rẹ̀ bọ ààyè rẹ̀.

12 "wọn gbogbo ohun èlò wọ́n ń fún iṣẹ́ ìsìn ibi mímọ́, wọn ó fi aṣọ aláwọ̀ búlúù yìí, wọn ó fi awọ seali ó, wọn ó fi gbé wọn ka orí férémù.

13 "wọn ó eérú kúrò lórí pẹpẹ idẹ, wọn ó tẹ́ aṣọ aláwọ̀ àlùkò e lórí. 14 Nígbà náà ni wọn ó gbogbo ohun èlò fún iṣẹ́ ìsìn níbi pẹpẹ, títí dórí àwo iná, fọ́̀ẹran, ọkọ́ eérú àti àwokòtò. wọn ó fi awọ ewúrẹ́ bo gbogbo rẹ̀, wọn ó fi òpó rẹ̀ bọ ààyè rẹ̀.

15 "Lẹ́yìn Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ ti parí bíbo ibi mímọ́ àti gbogbo ohun èlò ibi mímọ́, nígbà àgọ́ ṣetán láti tẹ̀síwájú, àwọn ọmọ Kohati bọ́ síwájú láti gbé e, ṣùgbọ́n wọn gbọdọ̀ fọwọ́ kan ohun mímọ́ kankan, wọ́n ṣe bẹ́̀ wọn ó . Àwọn ọmọ Kohati ni yóò gbé gbogbo ohun nínú àgọ́ ìpàdé.

16 "Iṣẹ́ Eleasari ọmọ Aaroni í ṣe àlùfáà ni ṣíṣe àbojútó òróró fìtílà, tùràrí dídùn, ẹbọ ohun jíjẹ ìgbà gbogbo àti òróró ìtasórí. ó jẹ́ alábojútó gbogbo ohun jẹ mọ́ àgọ́ àti gbogbo ohun nínú rẹ̀, pẹ̀gbogbo ohun èlò ibi mímọ́."

17 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni , 18 "i a ̀Kohati kúrò lára àwọn ọmọ Lefi. 19 Nítorí wọ́n , wọ́n ba à nígbà wọ́n súnmọ́ tòsí àwọn ohun mímọ́ jùlọ: Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ ni ó wọ ibi mímọ́ láti pín iṣẹ́ oníkálùkù àti àwọn ohun wọn yóò gbé. 20 Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Kohati gbọdọ̀ wọlé láti wo àwọn ohun mímọ́, tilẹ̀ jẹ́ ìṣẹ́kan, wọ́n ṣe bẹ́̀, wọn yóò ."

Àwọn ọmọ Gerṣoni

21 Olúwa sọ fún Mose , 22 "Tún ka iye àwọn ọmọ Gerṣoni nípa ilé baba wọn àti ìdílé wọn. 23 Ka gbogbo ọkùnrin láti ọmọ ọgbọ̀n ọdún títí àádọ́ta ọdún, gbogbo àwọn ń ṣiṣẹ́ àgọ́ ìpàdé.

24 "Èyí ni iṣẹ́ ìsìn ìdílé àwọn ọmọ Gerṣoni, wọ́n ti ń ṣiṣẹ́ àti ẹrù rírù. 25 Àwọn ni yóò máa ru àwọn aṣọ títa ti àgọ́, ti àgọ́ ìpàdé àti ìbòrí rẹ̀, àti awọ ewúrẹ́ a fi ó, aṣọ títa ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé, 26 aṣọ títa ti àgbàlá àgọ́ àti pẹpẹ , aṣọ títa ti ẹnu-ọ̀àbáwọlé àgbàlá, okùn àti àwọn ohun èlò iṣẹ́ ìsìn, àti ohun gbogbo à ń fún wọn, bẹ́̀ ni wọn ó máa sìn. Àwọn ọmọ Gerṣoni ni yóò ṣe gbogbo ohun yẹ pẹ̀àwọn nǹkan wọ̀nyí. 27 Gbogbo iṣẹ́ ìsìn àwọn ọmọ Gerṣoni yálà ni iṣẹ́ ṣíṣe tàbí ẹrù rírù ni, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ ni yóò máa darí wọn; ìwọ ni o yàn ẹrù oníkálùkù yóò fún un. 28 Èyí ni iṣẹ́ ìdílé àwọn Gerṣoni ni àgọ́ ìpàdé Itamari, ọmọ Aaroni í ṣe àlùfáà ni yóò jẹ alábojútó iṣẹ́ wọn.

Àwọn ọmọ Merari

29 "Ka iye àwọn ọmọ Merari nípa ilé baba wọn àti ìdílé wọn. 30 Ka gbogbo ọkùnrin láti ọmọ ọgbọ̀n ọdún títí àádọ́ta ọdún, gbogbo àwọn ń ṣiṣẹ́ àgọ́ ìpàdé. 31 Iṣẹ́ wọn yóò máa ṣe nínú àgọ́ ìpàdé nìyìí: gbígbẹ́ àwọn férémù àgọ́, pákó ìdábùú rẹ̀, òpó àti ihò òpó rẹ̀, 32 pẹ̀gbogbo òpó àgbàlá àti ohun èlò jẹ mọ́ lílò wọn, o yan ohun oníkálùkù yóò fún un. 33 Èyí ni iṣẹ́ ìsìn ìdílé àwọn ọmọ Merari, wọn yóò ti máa ṣiṣẹ́ àgọ́ ìpàdé lábẹ́ àkóso Itamari ọmọ Aaroni í ṣe àlùfáà."

Àbájáde kíka àwọn ọmọ Lefi

34 Mose àti Aaroni pẹ̀àwọn olórí ìjọ ènìyàn ka àwọn ọmọ Kohati nípa ìdílé àti ilé baba wọn.

35 Gbogbo ọmọkùnrin láti ọmọ ọgbọ̀n ọdún títí àádọ́ta ọdún gbogbo àwọn ń ṣiṣẹ́ Àgọ́ ìpàdé. 36 Iye wọn nípa ìdílé jẹ́ ẹgbẹ̀rìnlá ó dín làádọ́ta (2,750). 37 Èyí ni àpapọ̀ iye àwọn ọmọ Kohati ń ṣiṣẹ́ àgọ́ ìpàdé; Mose àti Aaroni gẹ́gẹ́ Olúwa ti pa á láṣẹ fún Mose.

38 Wọ́n ka àwọn ọmọ Gerṣoni nípa ìdílé àti ilé baba wọn.

39 Gbogbo ọmọkùnrin láti ọmọ ọgbọ̀n ọdún títí àádọ́ta, gbogbo àwọn ṣiṣẹ́ àgọ́ ìpàdé. 40 Iye wọn nípa ìdílé àti ilé baba wọn jẹ́ ẹgbẹ̀tàlá ó ọgbọ̀n (2,630). 41 Èyí jẹ́ àpapọ̀ iye àwọn ọmọ Gerṣoni, àwọn ṣiṣẹ́ àgọ́ ìpàdé. Mose àti Aaroni ṣe àṣẹ Olúwa.

42 Wọ́n ka àwọn ọmọ Merari nípa ìdílé àti ilé baba wọn.

43 Gbogbo ọkùnrin láti ọmọ ọgbọ̀n ọdún títí àádọ́ta ọdún, àwọn ṣiṣẹ́ àgọ́ ìpàdé. 44 Iye wọn nípa ìdílé àti ilé baba wọn jẹ́ ẹgbẹ̀rìndínlógún (3,200). 45 Èyí ni àpapọ̀ iye àwọn ọmọ Merari. Mose àti Aaroni wọ́n gẹ́gẹ́ àṣẹ Olúwa láti ẹnu Mose.

46 Gbogbo àwọn a nínú àwọn ọmọ Lefi, ti Mose àti Aaroni àti àwọn olórí Israẹli , nípa ìdílé wọn àti gẹ́gẹ́ ilé baba wọn. 47 Gbogbo ọkùnrin láti ọmọ ọgbọ̀n ọdún títí àádọ́ta, àwọn ń ṣiṣẹ́ ìsìn ń ru àwọn ẹrù inú Àgọ́ ìpàdé. 48 Àpapọ̀ iye wọn jẹ́ ẹgbẹ̀tàlá lẹ́gbàarin ó dín ogún (8,580). 49 Wọ́n yan iṣẹ́ àti àwọn ohun ẹni kọ̀̀kan yóò máa gbé fún un gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ láti ẹnu Mose.

Bẹ́̀ ni wọ́n ṣe wọ́n gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também