Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 8

Gbígbé ̀fìtílà

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 "Aaroni sọ̀rọ̀ o fún un . Nígbà ó ń to àwọn fìtílà, àwọn fìtílà méjèèje gbọdọ̀ tan ìmọ́lẹ̀ àyíká níwájú ̀fìtílà.’ "

3 Aaroni ṣe bẹ́̀; ó to àwọn fìtílà náà wọ́n fi kojú síwájú lórí ̀fìtílà gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose. 4 a ṣe ṣe ̀fìtílà náà nìyìí, a ṣe é láti ara wúrà lílù: láti ìsàlẹ̀ títí ibi ìtànná rẹ̀. Wọ́n ṣe ̀fìtílà náà gẹ́gẹ́ bátànì Olúwa fihan Mose.

Ìyàsọ́tọ̀ àwọn ọmọ Lefi

5 Olúwa sọ fún Mose , 6 8.6-26: Nu 3.5-13."Yọ àwọn ọmọ Lefi kúrò láàrín àwọn ọmọ Israẹli yòókù, o wẹ̀ wọ́n mọ́. 7 Báyìí ni o ṣe wẹ̀ wọ́n mọ́. Wọ́n omi ìwẹ̀nùmọ́ wọn lára, wọn ó irun ara wọn, wọn ó fọ aṣọ wọn, wọn ó ba à wẹ ara wọn mọ́ nípa ṣíṣe bẹ́̀. 8 Jẹ́ wọn ó akọ ̀dọ́ màlúù pẹ̀ẹbọ ohun jíjẹ rẹ̀ í ṣe ìyẹ̀fun ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára a fi òróró , ìwọ náà akọ ̀dọ́ màlúù kejì fún ẹbọ ̀ṣẹ̀. 9 Ìwọ ó àwọn ọmọ Lefi síwájú àgọ́ ìpàdé, o gbogbo àpapọ̀ ọmọ Israẹli jọ síbẹ̀ pẹ̀. 10 Báyìí ni o àwọn ọmọ Lefi síwájú Olúwa, gbogbo ọmọ Israẹli yóò gbọ́wọ́ àwọn ọmọ Lefi lórí. 11 Aaroni yóò àwọn ọmọ Lefi síwájú Olúwa gẹ́gẹ́ ọrẹ fífì láti ̀dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli , wọn máa ṣiṣẹ́ Olúwa.

12 "Lẹ́yìn àwọn ọmọ Lefi gbé ọwọ́ wọn orí àwọn akọ ọmọ màlúù náà, ìwọ yóò fi ̀kan ẹbọ ̀ṣẹ̀ àti èkejì fún ẹbọ sísun Olúwa, láti ṣe ètùtù fún àwọn ọmọ Lefi. 13 àwọn ọmọ Lefi dúró níwájú Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ ó gbé wọn kalẹ̀ gẹ́gẹ́ ọrẹ fífì Olúwa. 14 Báyìí ni ìwọ yóò ṣe ya ọmọ Lefi sọ́tọ̀, kúrò láàrín àwọn ọmọ Israẹli yòókù, àwọn ọmọ Lefi yóò jẹ́ tèmi.

15 "Lẹ́yìn ó ti wẹ àwọn ọmọ Lefi mọ́, ó ti gbé wọn kalẹ̀ ẹbọ fífì nígbà náà ni wọn ó lọ máa ṣiṣẹ́ nínú àgọ́ ìpàdé. 16 Nítorí àwọn ni ó jẹ́ ti Èmi pátápátá nínú àwọn ọmọ Israẹli. Mo ti gbà wọ́n fún ara mi dípò àwọn àkọ́àní àkọ́ọkùnrin gbogbo Israẹli. 17 Nítorí gbogbo àkọ́ọmọ lọ́kùnrin Israẹli jẹ́ tèmi, ti ènìyàn àti ti ẹranko, láti ọjọ́ mo ti pa gbogbo àkọ́ilẹ̀ Ejibiti ni mo ti wọ́n sọ́tọ̀ fún ara mi. 18 8.18: Nu 3.11-13,45.Mo ti gba àwọn ọmọ Lefi dípò gbogbo àkọ́ọmọ ọkùnrin nínú Israẹli. 19 Nínú Israẹli, mo fi àwọn ọmọ Lefi fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ gẹ́gẹ́ ̀bùn láti máa ṣiṣẹ́ nínú àgọ́ ìpàdé fun àwọn ọmọ Israẹli àti láti máa ṣe ètùtù fún wọn àjàkálẹ̀-ààrùn ba à kọlu àwọn ọmọ Israẹli nígbà wọ́n súnmọ́ ibi mímọ́."

20 Mose, Aaroni àti gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli ṣe fún àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose. 21 Àwọn ọmọ Lefi wẹ ara wọn mọ́, wọ́n fọ aṣọ wọn. Aaroni wọn gẹ́gẹ́ ọrẹ fífì níwájú Olúwa, Aaroni ṣe ètùtù fún wọn láti wẹ̀ wọ́n mọ́. 22 Lẹ́yìn èyí àwọn ọmọ Lefi lọ sínú àgọ́ ìpàdé láti lọ máa ṣiṣẹ́ wọn lábẹ́ àbojútó Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀. Wọ́n ṣe fún àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

23 Olúwa sọ fún Mose , 24 "Èyí ni ohun jẹ mọ́ àwọn ọmọ Lefi, láti ọmọ ọdún kẹẹdọ́gbọ̀n (25) tàbí bẹ́̀ lọ ni ó máa kópa nínú iṣẹ́ àgọ́ ìpàdé. 25 Ṣùgbọ́n ẹni ti ọmọ àádọ́ta ọdún gbọdọ̀ ṣíwọ́ nínú iṣẹ́ ojoojúmọ́ wọn nínú àgọ́, wọ́n ṣiṣẹ́ mọ́. 26 Wọ́n le máa ran àwọn arákùnrin wọn lọ́wọ́ nínú àgọ́ ìpàdé ṣùgbọ́n àwọn fúnra wọn gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan. Báyìí ni o ṣe pín iṣẹ́ fún àwọn ọmọ Lefi."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também