Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 1

Ìkànìyàn

1 1.1-46: Nu 26.1-51. Olúwa Mose sọ̀rọ̀ aginjù Sinai nínú àgọ́ àjọ ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kejì ọdún kejì àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti, ó , 2 "Ka gbogbo àgbájọ ènìyàn Israẹli nípa ẹbí wọn, àti nípa ìdílé baba wọn, to orúkọ wọn olúkúlùkù ọkùnrin ̀kọ̀̀kan. 3 Ìwọ àti Aaroni ni gbogbo ọmọkùnrin Israẹli gẹ́gẹ́ ìpín wọn láti ọmọ ogún ọdún sókè, àwọn ó lọ sójú ogun. 4 ọkùnrin kọ̀̀kan láti inú olúkúlùkù ̀ó pẹ̀yín, olúkúlùkù jẹ́ olórí ilé àwọn baba rẹ̀.

5 "Orúkọ àwọn ọkùnrin yóò ràn ́ lọ́wọ́ nìyí:

"Láti ̀dọ̀ Reubeni, Elisuri ọmọ Ṣedeuri.

6 Láti ̀dọ̀ Simeoni, Ṣelumieli ọmọ Suriṣaddai.

7 Láti ̀dọ̀ Juda, Nahiṣoni ọmọ Amminadabu.

8 Láti ̀dọ̀ Isakari, Netaneli ọmọ Suari.

9 Láti ̀dọ̀ Sebuluni, Eliabu ọmọ Heloni.

10 Láti ̀dọ̀ àwọn ọmọ Josẹfu:

láti ̀dọ̀ Efraimu, Eliṣama ọmọ Ammihudu.

Láti ̀dọ̀ Manase, Gamalieli ọmọ Pedasuri.

11 Láti ̀dọ̀ Benjamini, Abidani ọmọ Gideoni.

12 Láti ̀dọ̀ Dani, Ahieseri ọmọ Ammiṣaddai.

13 Láti ̀dọ̀ Aṣeri, Pagieli ọmọ Okanri.

14 Láti ̀dọ̀ Gadi, Eliasafu ọmọ Deueli.

15 Láti ̀dọ̀ Naftali, Ahira ọmọ Enani."

16 Àwọn wọ̀nyí ni wọ́n yàn nínú àwùjọ ènìyàn, olórí àwọn ̀baba wọn. Àwọn ni olórí àwọn ẹbí Israẹli.

17 Mose àti Aaroni àwọn ènìyàn a dárúkọ wọ̀nyí 18 wọ́n pe gbogbo àwùjọ ènìyàn Israẹli jọ ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kejì. Àwọn ènìyàn dárúkọ baba ńlá wọn nípa ẹbí àti ìdílé wọn. Wọ́n ṣe àkọsílẹ̀ orúkọ àwọn ọmọkùnrin ̀kọ̀̀kan láti ọmọ ogún ọdún sókè, 19 gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose. Bẹ́̀ náà ṣe wọ́n nínú aginjù Sinai.

20 Láti ìran Reubeni í ṣe àkọ́Israẹli, gbogbo ọmọkùnrin ọjọ́ orí wọn jẹ́ ogún ọdún sókè wọ́n lọ sójú ogun ni wọ́n to orúkọ wọn, lẹ́yọ kọ̀̀kan gẹ́gẹ́ àkọsílẹ̀ ẹbí àti ìdílé wọn. 21 Àwọn a ̀Reubeni jẹ́ ẹgbàá mẹ́tàlélógún ó ̀́dẹ́gbẹ̀ta (46,500).

22 Láti ìran Simeoni, gbogbo ọmọkùnrin ọjọ́ orí wọn jẹ́ ogún ọdún sókè, wọ́n lọ sójú ogun ni wọ́n , wọ́n to orúkọ wọn lẹ́yọ kọ̀̀kan gẹ́gẹ́ àkọsílẹ̀ ẹbí àti ìdílé wọn. 23 Iye àwọn á nínú ̀Simeoni jẹ́ ẹgbàá mọ́kàndínlọ́gbọ̀n ó ̀́dúnrún (59,300).

24 Láti ìran Gadi, gbogbo ọmọkùnrin ọjọ́ orí wọn jẹ́ ogún ọdún sókè wọ́n lọ sójú ogun ni wọ́n to orúkọ wọn lẹ́yọ kọ̀̀kan, gẹ́gẹ́ ẹbí àti ìdílé wọn. 25 Iye àwọn a nínú ̀Gadi jẹ́ ẹgbàá méjìlélógún ó àádọ́talélẹ́gbẹ̀jọ (45,650).

26 Láti ìran Juda, gbogbo ọmọkùnrin ọjọ́ orí wọn jẹ́ ogún ọdún sókè, wọ́n le lọ sójú ogun ni wọ́n to orúkọ wọn lẹ́yọ kọ̀̀kan gẹ́gẹ́ àkọsílẹ̀ ẹbí àti ìdílé wọn. 27 Iye a nínú ̀Juda jẹ́ ẹgbàá mẹ́tàdínlógójì ó ẹgbẹ̀ta (74,600).

28 Láti ìran Isakari, gbogbo ọmọkùnrin ọjọ́ orí wọn jẹ́ ogún ọdún sókè wọ́n le lọ sójú ogun ni wọ́n to orúkọ wọn lẹ́yọ kọ̀̀kan àkọsílẹ̀ ẹbí àti ìdílé wọn. 29 Iye a nínú ̀Isakari jẹ́ ẹgbàá mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ó irinwó (54,400).

30 Láti ìran Sebuluni, gbogbo ọmọkùnrin ọjọ́ orí wọn jẹ́ ogún ọdún sókè wọ́n lọ sójú ogun ni wọ́n to orúkọ wọn lẹ́yọ kọ̀̀kan gẹ́gẹ́ àkọsílẹ̀ ẹbí àti ìdílé wọn. 31 Iye a nínú ̀Sebuluni jẹ́ ẹgbàá méjìdínlọ́gbọ̀n ó egbèje (57,400).

32 Láti inú àwọn ọmọ Josẹfu.

Láti ìran Efraimu, gbogbo ọmọkùnrin ọjọ́ orí wọ́n jẹ́ ogún ọdún sókè wọ́n lọ sójú ogun ni wọ́n to orúkọ wọn lẹ́yọ kọ̀̀kan gẹ́gẹ́ àkọsílẹ̀ ẹbí àti ìdílé wọn. 33 Iye a nínú ̀Efraimu jẹ́ ̀kẹ́ méjì ó ̀́dẹ́gbẹ̀ta (40,500).

34 Láti ìran Manase, gbogbo ọmọkùnrin ọjọ́ orí wọn jẹ́ ogún ọdún sókè, wọ́n lọ sójú ogun ni wọ́n to orúkọ wọn lẹ́yọ kọ̀̀kan gẹ́gẹ́ àkọsílẹ̀ ẹbí àti ìdílé wọn. 35 Iye a nínú ̀Manase jẹ́ ẹgbàá ẹẹ́rìndínlógún ó igba (32,200).

36 Láti ìran Benjamini, gbogbo ọmọkùnrin ọjọ́ orí wọn jẹ́ ogún ọdún sókè ni wọ́n to orúkọ wọn lẹ́yọ kọ̀̀kan gẹ́gẹ́ àkọsílẹ̀ ẹbí àti ìdílé wọn. 37 Iye a nínú ̀Benjamini jẹ́ ẹgbàá mẹ́tàdínlógún ó egbèje (35,400).

38 Láti ìran Dani, gbogbo ọmọkùnrin ọjọ́ orí wọn jẹ́ ọmọ ogún ọdún sókè, wọ́n lọ sójú ogun ni wọ́n to orúkọ wọn lẹ́yọ kọ̀̀kan gẹ́gẹ́ àkọsílẹ̀ ẹbí àti ìdílé wọn. 39 Iye a nínú ̀Dani jẹ́ ẹgbàá mọ́kànlélọ́gbọ̀n ó ̀́dẹ́gbẹ̀rin (62,700).

40 Láti ìran Aṣeri, gbogbo ọmọkùnrin ọjọ́ orí wọn jẹ́ ogún ọdún sókè, wọ́n le lọ sójú ogun ni wọ́n to orúkọ wọn lẹ́yọ kọ̀̀kan gẹ́gẹ́ àkọsílẹ̀ ẹbí àti ìdílé wọn. 41 Iye a nínú ̀Aṣeri jẹ́ ̀kẹ́ méjì ó ̀́dẹ́gbẹ̀jọ (41,500).

42 Láti ìran Naftali, gbogbo ọmọkùnrin ọjọ́ orí wọn jẹ́ ogún ọdún ó , wọ́n lọ sójú ogun ni wọ́n to orúkọ wọn lẹ́yọ kọ̀̀kan gẹ́gẹ́ àkọsílẹ̀ ẹbí àti ìdílé wọn. 43 Iye àwọn a nínú ̀Naftali jẹ́ ẹgbàá mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ó egbèje (53,400).

44 Wọ̀nyí ni àwọn ènìyàn Mose àti Aaroni , pẹ̀ìrànlọ́wọ́ àwọn olórí méjìlá fún Israẹli, ẹnìkọ̀̀kan ṣojú fún ìdílé rẹ̀. 45 Gbogbo ọmọkùnrin Israẹli jẹ́ ọmọ ogún ọdún sókè, lọ sójú ogun ni wọ́n gẹ́gẹ́ ìdílé wọn. 46 Àpapọ̀ iye wọn jẹ́ ọgbọ̀n ̀kẹ́ ó egbèjìdínlógún dín làádọ́ta (603,550).

47 1.47: Nu 2.33. A ka àwọn ìdílé ̀Lefi mọ́ àwọn ìyókù. 48 Nítorí Olúwa ti sọ fún Mose , 49 "Ìwọ gbọdọ̀ ka ̀Lefi, tàbí o wọ́n mọ́ àwọn ọmọ Israẹli. 50 1.50-53: Nu 3.5-8,21-37; 4.1-33; 8.19; 18.3,4,23.Dípò èyí yan àwọn ọmọ Lefi láti jẹ́ alábojútó àgọ́ ̀, lórí gbogbo ohun èlò àti ohun gbogbo jẹ́ ti àgọ́ ̀. Àwọn ni yóò máa gbé àgọ́ àti gbogbo ohun èlò rẹ̀, wọn ó máa mójútó o, wọn ó máa pàgọ́ i . 51 Ìgbàkígbà àgọ́ yóò tẹ̀síwájú, àwọn ọmọ Lefi ni yóò palẹ̀, nígbàkígbà a tún pa àgọ́, àwọn ọmọ Lefi náà ni yóò ṣe é. Àlejò súnmọ́ tòsí ibẹ̀, pípa ni pa á 52 àwọn ọmọ Israẹli pa àgọ́ wọn gẹ́gẹ́ ìpín wọn olúkúlùkù ibùdó tirẹ̀ lábẹ́ ̀págun tirẹ̀. 53 Àwọn ọmọ Lefi yóò jẹ́ alábojútó àti olùtọ́àgọ́ ̀náà, ìbínú ba à lára ìjọ àwọn ọmọ Israẹli; àwọn ọmọ Lefi máa ṣe ìtọ́àgọ́ ̀náà."

54 Àwọn ọmọ Israẹli ṣe ohun gbogbo gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também