Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 22

Balaki ránṣẹ́ Balaamu

1 22.1: Nu 33.48. Nígbà náà àwọn ọmọ Israẹli rin ìrìnàjò lọ pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu wọ́n pa ibùdó lẹ́gbẹ̀́ Jordani ó kọjá lọ Jeriko.

2 Nísinsin yìí, Balaki ọmọ Sippori gbogbo ohun àwọn Israẹli ti ṣe àwọn ará Amori, 3 ̀ba Moabu nítorí ̀pọ̀ ènìyàn níbẹ̀ nítòótọ́, Moabu kún fún ̀nítorí àwọn ọmọ Israẹli.

4 Moabu sọ fún àwọn àgbàgbà Midiani , "Nísinsin yìí ni àwọn wọ̀nyí yóò gbogbo ohun ó wa , màlúù ṣe ń jẹ koríko ó nínú oko."

Bẹ́̀ ni Balaki ọmọ Sippori, ó jẹ́ ọba Moabu nígbà náà, 5 rán oníṣẹ́ Balaamu ọmọ Beori, ó Petori, ̀odò Eufurate, ti ilẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ. Balaki sọ ,

"Àwọn ènìyàn kan jáde láti Ejibiti; wọ́n bo gbogbo ilẹ̀ ayé wọ́n pa ibùdó súnmọ́ ̀dọ̀ mi. 6 Nísinsin yìí, fi àwọn ènìyàn wọ̀nyí , nítorí wọ́n agbára fún mi. Nípa ṣíṣe èyí èmi ó ṣẹ́gun wọn, n wọn kúrò ilẹ̀ yìí. Nítorí mo mọ̀ ìbùkún ni fún àwọn ìwọ bùkún, ìfibú ni ẹni ìwọ fi ."

7 Àti àwọn àgbàgbà Moabu àti Midiani lọ pẹ̀owó àyẹ̀lọ́wọn, nígbà wọ́n ̀dọ̀ Balaamu, wọ́n sọ nǹkan Balaki sọ fún wọn.

8 "sùn níbí lálẹ́ yìí," Balaamu sọ fún un , "èmi ó padà fún un yín èsì nǹkan Olúwa fún mi." Nítorí àwọn ìjòyè Moabu dúró sọ́dọ̀ rẹ̀.

9 Ọlọ́run tọ Balaamu ó , "Ta ni àwọn ọkùnrin ó pẹ̀rẹ yìí?"

10 Balaamu sọ fún Ọlọ́run , "Balaki ọmọ Sippori, ọba Moabu, rán iṣẹ́ yìí mi , 11 Àwọn ènìyàn kan ti ilẹ̀ Ejibiti jáde wọ́n bo ojú ilẹ̀. Nísinsin yìí, , o fi wọ́n fún mi. Bóyá èmi yóò wọn , èmi ó wọn jáde.’ "

12 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run sọ fún Balaamu , "ṣe wọn lọ. Ìwọ gbọdọ̀ ègún àwọn ènìyàn náà lórí, nítorí a ti bùkún wọn."

13 òwúrọ̀ ọjọ́ kejì Balaamu dìde ó sọ fún àwọn ìjòyè Balaki , "padà orílẹ̀-èdè yín, nítorí Olúwa ti kọ̀ láti jẹ́ n tẹ̀yín."

14 Nígbà náà àwọn ìjòyè Moabu padà tọ Balaki lọ wọ́n , "Balaamu kọ̀ láti tẹ̀wa."

15 Nígbà náà Balaki rán àwọn ìjòyè mìíràn wọ́n pọ̀ àwọn wọ́n níyì ju alákọ́kọ́ lọ. 16 Wọ́n lọ ̀dọ̀ Balaamu wọ́n sọ ,

"Èyí ni ohun Balaki ọmọ Sippori sọ, ṣe jẹ́ ohunkóhun ó ́ lọ́láti ̀dọ̀ mi, 17 nítorí èmi yóò fún ̀bùn dáradára, èmi yóò ṣe ohunkóhun ìwọ sọ. , o fi àwọn ènìyàn wọ̀nyí fún mi."

18 Ṣùgbọ́n Balaamu wọn lóhùn , "Kódà Balaki fún mi ààfin rẹ̀ ó kún fún fàdákà àti wúrà, èmi ṣe ohunkóhun ó tóbi tàbí kéré ó kọjá òfin Olúwa Ọlọ́run mi. 19 Nísinsin yìí dúró níbí di ọjọ́ kejì gẹ́gẹ́ àwọn tókù ti ṣe nígbà náà èmi yóò mọ ohun Olúwa yóò tún sọ fún mi."

20 alẹ́ ọjọ́ náà Ọlọ́run tọ Balaamu ó sọ , "Nígbà ọkùnrin yìí ti ́, lọ pẹ̀wọn, ṣùgbọ́n ẹnu nǹkan mo sọ fún ni o ṣe."

Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ Balaamu

21 Balaamu dìde òwúrọ̀, ó di ẹrù kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ òun pẹ̀àwọn ìjòyè Moabu. 22 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run bínú gidigidi, angẹli Olúwa dúró lójú ̀láti dojú ìjà kọ ́. Balaamu ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ lọ, àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ méjì pẹ̀rẹ̀. 23 Nígbà kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà angẹli Olúwa ó dúró ojú ̀pẹ̀idà a fàyọ ọwọ́ rẹ̀, ó kọjú kúrò ̀lọ sínú oko. Balaamu ú ó gbé òhun padà lọ ojú ̀.

24 Nígbà náà angẹli Olúwa dúró ojú ̀tóóró láàrín ọgbà àjàrà, pẹ̀ògiri ̀méjèèjì. 25 Nígbà kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ angẹli Olúwa, ó lẹ̀ mọ́ ̀gbẹ́ ògiri, ó rún ẹsẹ̀ Balaamu mọ́ ògiri. Nígbà náà, ó tún án, lẹ́̀kan i.

26 Nígbà náà angẹli Olúwa súnmọ́ wájú ó dúró níbi ̀tóóró níbi ti ̀láti yípadà, bóyá ̀tún tàbí òsì. 27 Nígbà kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ angẹli Olúwa, ó jókòó abẹ́ Balaamu, inú i án pẹ̀̀rẹ̀. 28 Nígbà náà Olúwa ṣí ẹnu kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ó sọ fún Balaamu , "ni mo ṣe fún o fi lẹ́̀mẹ́ta?"

29 Balaamu sọ fún kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ , "Nítorí ìwọ fi ṣẹ̀sín! mo idà ọwọ́ ni èmi ìbá pa ́ nísinsin yìí."

30 Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ sọ fún Balaamu , "Ṣé mi í ṣe kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ ni, o máa ń gùn gbogbo ìgbà, láti ìgbà pípẹ́ ? Ǹjẹ́ mo hu irú ìwà báyìí ?"

"Rárá," Ó dáhùn.

31 Nígbà náà Olúwa ṣí ojú Balaamu, ó angẹli Olúwa ó dúró ojú ̀pẹ̀idà rẹ̀ ó fàyọ. Ó tẹ orí rẹ̀ ba.

32 Nígbà náà angẹli Olúwa béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "ni ó o fi na kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ nígbà mẹ́ta yìí? Mo síbí láti kọ ojú ìjà nítorí ̀rẹ tọ́ níwájú mi. 33 Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mi ó kúrò fún mi lẹ́̀mẹ́ta yìí. ó jẹ́ kúrò. Èmi ìbá ti pa ́ pátápátá nísinsin yìí, ṣùgbọ́n Èmi yóò òun ."

34 Balaamu sọ fún angẹli Olúwa , "Mo ti dẹ́ṣẹ̀, èmi mọ̀ o dúró níwájú ̀láti dojúkọ , nísinsin yìí inú rẹ dùn, èmi ó padà."

35 Angẹli Olúwa sọ fún Balaamu , "Lọ pẹ̀àwọn arákùnrin náà, ṣùgbọ́n nǹkan mo sọ fún nìkan ni o sọ." Nígbà náà Balaamu lọ pẹ̀àwọn ìjòyè Balaki.

36 Nígbà Balaki gbọ́ Balaamu ń bọ̀ , ó jáde lọ láti lọ pàdé rẹ̀ ìlú Moabu ó agbègbè Arnoni, ̀gbẹ́ ilẹ̀ rẹ̀. 37 Balaki sọ fún Balaamu , "Ǹjẹ́ èmi a ránṣẹ́ kánjúkánjú ? ìwọ fi ̀dọ̀ mi? Ṣé èmi láti sọ ́ di ẹni ńlá?"

38 Balaamu fún Balaki , "Kíyèsi, èmi tọ̀ ́ , èmi ha agbára kan nísinsin yìí rárá láti ohun kan? Mo gbọdọ̀ sọ nǹkan Ọlọ́run fi mi lẹ́nu."

39 Nígbà náà Balaamu lọ pẹ̀Balaki Kiriati-Hosotia. 40 Balaki ẹbọ akọ màlúù pẹ̀àgùntàn, ó fún Balaamu díẹ̀ pẹ̀àwọn ìjòyè ó ̀dọ̀ rẹ̀. 41 òwúrọ̀ ọjọ́ kejì Balaki gbé Balaamu lọ Bamoti Baali, láti ibẹ̀ ti apá kan àwọn ènìyàn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também