Pular para o conteúdo
Publicidade

Nehemiah 11

Àwọn olùgbé tuntun Jerusalẹmu

1 Nísinsin yìí àwọn olórí àwọn ènìyàn tẹ̀Jerusalẹmu, àwọn ènìyàn tókù dìbò láti ẹnìkọ̀̀kan jáde nínú àwọn mẹ́wàá mẹ́wàá láti máa gbé Jerusalẹmu, ìlú mímọ́, nígbà àwọn mẹ́sàn-án tókù yóò dúró àwọn ìlú u wọn. 2 Àwọn ènìyàn súre fún gbogbo àwọn ọkùnrin wọ́n jọ̀wọ́ ara wọn láti gbé Jerusalẹmu.

3 11.3-22: 1Ki 9.2-34. Wọ̀nyí ni àwọn olórí agbègbè ìjọba wọ́n tẹ̀Jerusalẹmu (díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Israẹli àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi, àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti àwọn ìran àwọn ìránṣẹ́ Solomoni ń gbé àwọn ìlú Juda, olúkúlùkù ń gbé lórí ilẹ̀ ìní rẹ̀ àwọn ìlú náà. 4 Nígbà àwọn ènìyàn tókù nínú àwọn Juda àti Benjamini ń gbé Jerusalẹmu).

Nínú àwọn ọmọ Juda:

Ataiah ọmọ Ussiah ọmọ Sekariah, ọmọ Amariah, ọmọ Ṣefatia, ọmọ Mahalaleli, ìran Peresi;

5 àti Maaseiah ọmọ Baruku, ọmọ Koli-Hose, ọmọ Hasaiah, ọmọ Adaiah, ọmọ Joiaribu, ọmọ Sekariah, ọmọ Ṣilo.

6 Àwọn ìran Peresi gbé Jerusalẹmu jẹ́ àádọ́rinlénírinwó ó dín méjì (468) alágbára ọkùnrin.

7 Nínú àwọn ìran Benjamini:

Sallu ọmọ Meṣullamu, ọmọ Joẹdi, ọmọ Pedaiah, ọmọ Kolaiah, ọmọ Maaseiah, ọmọ Itieli, ọmọ Jeṣaiah, 8 àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, Gabbai àti Sallai jẹ́ ̀rìndínlẹ́gbẹ̀rún ó mẹ́jọ (928) ọkùnrin.

9 Joẹli ọmọ Sikri ni olórí òṣìṣẹ́ wọn, Juda ọmọ Hasenuah ni olórí agbègbè kejì ìlú náà.

10 Nínú àwọn àlùfáà:

Jedaiah; ọmọ Joiaribu; Jakini;

11 Seraiah ọmọ Hilkiah, ọmọ Meṣullamu, ọmọ Sadoku, ọmọ Meraioti, ọmọ Ahitubu, àwọn ni olórí ń bojútó ilé Ọlọ́run, 12 àti àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn, ẹni ó ń ṣe iṣẹ́ tẹmpili jẹ́ ẹgbẹ̀rin ó mẹ́rìnlélógún (822) ọkùnrin:

Adaiah ọmọ Jerohamu, ọmọ Pelaiah, ọmọ Amisi, ọmọ Sekariah, ọmọ Paṣuri, ọmọ Malkiah, 13 àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ wọ́n jẹ́ olórí ìdílé jẹ́ òjìlúgba ó méjì (242) ọkùnrin:

Amaṣai ọmọ Asareeli, ọmọ Ahsai, ọmọ Meṣilemoti, ọmọ Immeri, 14 àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ wọ́n jẹ́ alágbára ọkùnrin jẹ́ méjìdínláàádóje (128).

Olórí òṣìṣẹ́ wọn ni Sabdieli ọmọ Hagedolimu.

15 Láti inú àwọn ọmọ Lefi:

Ṣemaiah ọmọ Haṣubu, ọmọ Asrikamu, ọmọ Haṣabiah ọmọ Bunni;

16 Ṣabbetai àti Josabadi, olórí méjì nínú àwọn ọmọ Lefi, àwọn ó jẹ́ alábojútó iṣẹ́ ó ̀yìn àgbàlá ilé Ọlọ́run;

17 Mattaniah ọmọ Mika, ọmọ Sabdi, ọmọ Asafu, adarí ó ń ṣáájú ìdúpẹ́ àti àdúrà;

Bakbukiah ẹnìkejì láàrín àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀;

àti Abida ọmọ Ṣammua, ọmọ Galali, ọmọ Jedutuni.

18 Àwọn ọmọ Lefi nínú ìlú mímọ́ jẹ́ ̀rìnlélúgba ó mẹ́rin (284).

19 Àwọn aṣọ́:

Akkubu, Talmoni, àti àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn, wọ́n máa ń ṣọ́jẹ́ méjìléláàádọ́sàn-án (172) ọkùnrin.

20 Àwọn tókù nínú àwọn ọmọ Israẹli, pẹ̀àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, gbogbo ìlú u Juda, olúkúlùkù lórí ilẹ̀ ìní tirẹ̀.

21 Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili ń gbé lórí òkè Ofeli, Siha àti Giṣpa ni alábojútó wọn.

22 Olórí òṣìṣẹ́ àwọn ọmọ Lefi Jerusalẹmu Ussi ọmọ Bani, ọmọ Haṣabiah, ọmọ Mattaniah ọmọ Mika. Ussi jẹ́ ̀kan nínú àwọn ìran Asafu wọ́n jẹ́ akọrin ojúṣe nínú ìjọ́sìn ilé Ọlọ́run. 23 Àwọn akọrin abẹ́ àṣẹ ọba, èyí ó n díwọ̀n iṣẹ́ ojoojúmọ́ wọn.

24 Petahiah ọmọ Meṣesabeli, ̀kan nínú àwọn Sera ọmọ Juda aṣojú ọba nínú ohun gbogbo ó jẹ mọ́ ti àwọn ènìyàn náà.

25 Fún ìletò pẹ̀oko wọn, díẹ̀ nínú àwọn ènìyàn Juda ń gbé Kiriati-Arba, àti àwọn ìletò agbègbè e rẹ̀, Diboni àti ìletò rẹ̀, Jekabseeli. 26 Jeṣua, Molada, Beti-Peleti 27 Hasari-Ṣuali, Beerṣeba àti àwọn agbègbè rẹ̀. 28 Siklagi, Mekona àti àwọn ìletò rẹ̀, 29 Ẹni-Rimoni, Sora, Jarmatu, 30 Sanoa, Adullamu àti àwọn ìletò o wọn, Lakiṣi àti àwọn oko rẹ̀, àti Aseka àti àwọn ìletò rẹ̀. Bẹ́̀ ni wọ́n ń gbé láti Beerṣeba títí àfonífojì Hinnomu.

31 Àwọn ọmọ Benjamini láti Geba ń gbé Mikmasi, Aija, Beteli àti àwọn ìletò rẹ̀. 32 Anatoti, Nobu àti Ananiah, 33 Hasori Rama àti Gittaimu, 34 Hadidi, Seboimu àti Neballati, 35 Lodi àti Ono, àti àfonífojì àwọn gbẹ́nàgbẹ́.

36 Nínú ìpín àwọn ọmọ Lefi ni Juda tẹ̀Benjamini.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também