Pular para o conteúdo
Publicidade

Sefaniah 2

Ìpè si Ìrònúpìwàdà

1 ara yín jọ pọ̀, àní ra yín jọ pọ̀

orílẹ̀-èdè ìtìjú,

2 a pa àṣẹ náà, ọjọ́ náà kọjá ìyàngbò ọkà,

gbígbóná ìbínú Olúwa a yín,

ọjọ́ ìbínú Olúwa ó a yín.

3 Olúwa, gbogbo ̀yin onírẹ̀lẹ̀ ilẹ̀ náà,

̀yin ń ṣe ohun ó pàṣẹ.

òdodo, ìrẹ̀lẹ̀ pẹ̀,

bóyá á ó pa yín mọ́ ọjọ́ ìbínú Olúwa.

Ìlòdì Filistia

4 2.4-7: Isa 14.29-31; Jr 47; El 25.15-17; Jl 3.4-8; Am 1.6-8; Sk 9.5-7. Nítorí , a ó kọ Gasa sílẹ̀,

Aṣkeloni yóò dahoro.

̀sán gangan ni a ó Aṣdodu jáde,

a ó fa Ekroni tu kúrò.

5 Ègbé ni fún ̀yin ń gbé etí Òkun,

̀yin ènìyàn ara Kereti;

̀rọ̀ Olúwa dojúkọ ́, ìwọ Kenaani,

ilẹ̀ àwọn ara Filistini.

"Èmi yóò pa yín run,

ẹnìkan ṣẹ́nínú yín."

6 Ilẹ̀ náà etí Òkun, ni ibùgbé àwọn ará Kereti,

ni yóò jẹ́ ibùjókòó fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn àti agbo àgùntàn.

7 Agbègbè náà yóò jẹ́ ti ìyókù àwọn ilé Juda,

níbẹ̀ ni wọn yóò ti koríko fún ẹran.

ilé Aṣkeloni ni wọn yóò

dùbúlẹ̀ ni àṣálẹ́.

Olúwa Ọlọ́run wọn yóò bẹ̀ wọn ,

yóò ìgbèkùn wọn padà.

Ìlòdì Moabu àti Ammoni

8 2.8-11: Isa 15–16; 25.10-12; Jr 48; El 25.8-11; Am 2.1-3. "Èmi ti gbọ́ ̀gàn Moabu,

àti ẹlẹ́àwọn Ammoni,

àwọn kẹ́gàn àwọn ènìyàn mi,

wọ́n ti gbé ara wọn ga agbègbè wọn.

9 Nítorí náà, Èmi ,"

ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

Ọlọ́run àwọn Israẹli ,

"nítòótọ́ Moabu yóò dàbí Sodomu,

àti Ammoni yóò dàbí Gomorra,

ibi ó kún fún yèrèpè,

àti ìhó iyọ̀ àti ìdahoro títí láéláé.

Ìyókù àwọn ènìyàn mi yóò wọn;

àwọn ó yọ nínú ewu orílẹ̀-èdè mi ni yóò jogún ilẹ̀ wọn."

10 Èyí ni ohun wọn yóò gbà padà nítorí ìgbéraga wọn,

nítorí wọ́n kẹ́gàn, wọn ti fi àwọn ènìyàn Olúwa àwọn ọmọ-ogun ṣe ẹlẹ́.

11 Olúwa yóò jẹ́ ìbẹ̀fún wọn;

nígbà Òun pa gbogbo òrìṣà ilẹ̀ náà run.

Orílẹ̀-èdè láti etí odò yóò máa sìn,

olúkúlùkù láti ilẹ̀ rẹ̀ .

12 "̀yin Etiopia pẹ̀,

a ó fi idà mi pa yín."

Asiria

13 Òun yóò na ọwọ́ rẹ̀ apá àríwá,

yóò pa Asiria run,

yóò sọ Ninefe di ahoro,

àti di gbígbẹ aginjù.

14 Agbo ẹran yóò dùbúlẹ̀ ni àárín rẹ̀,

àti gbogbo ẹranko àwọn orílẹ̀-èdè.

Òwìwí aginjù àti ti n kígbe ẹyẹ òwìwí

yóò wọ ẹyẹ ni ọwọ̀n rẹ̀.

Ohùn wọn yóò kọrin ni ojú fèrèsé,

ìdahoro yóò nínú ìloro ẹnu-ọ̀,

òun yóò ṣẹ́ ̀kedari sílẹ̀.

15 Èyí ni ìlú aláyọ̀ ó ń gbé láìléwu.

Ó sọ fun ara rẹ̀ ,

"Èmi ni, ẹnìkan ó ń bẹ lẹ́yìn mi."

Irú ahoro wo ni òun ha ti jẹ́,

ibùgbé fún àwọn ẹranko igbó!

Gbogbo ẹni ó kọjá ̀dọ̀ rẹ̀

yóò fi rẹ́rìn-ín ẹlẹ́,

wọ́n yóò gbọn ẹsẹ̀ wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também

Sofonias
Ver todos os capítulos de Sofonias