Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 49

̀rọ̀ ìkẹyìn Jakọbu àwọn ọmọ rẹ̀

1 Nígbà náà ni Jakọbu ránṣẹ́ pe àwọn ọmọ rẹ̀, ó , "ara yín jọ pọ̀, n le è sọ ohun yóò ṣẹlẹ̀ ọjọ́ iwájú fún un yín.

2 "ara yín jọ pọ̀, tẹ́, ̀yin ọmọ Jakọbu;

fetí Israẹli baba yín.

3 "Reubeni, ìwọ ni àkọ́mi,

agbára mi, ìpilẹ̀ṣẹ̀ ipá mi,

títayọ ọlá àti títayọ agbára.

4 Ẹni ríru omi Òkun, ìwọ yóò tayọ mọ́,

nítorí ìwọ gun ibùsùn baba rẹ,

lórí àkéte mi, ìwọ á jẹ́

(ìwọ ̀kan nínú àwọn aya baba rẹ lòpọ̀).

5 "Simeoni àti Lefi jẹ́ arákùnrin

idà wọn jẹ́ ohun èlò ogun alágbára.

6 ọkàn mi ṣe ni àṣepọ̀ pẹ̀wọn,

n ṣe dúró níbí ìpéjọpọ̀ wọn,

nítorí wọ́n ti pa àwọn ènìyàn ìbínú wọn,

wọ́n da àwọn màlúù lóró ó ti wọ́n.

7 Ìfibú ni ìbínú wọn nítorí ó gbóná púpọ̀,

àti fún ìrunú wọn nítorí ó kún fún ìkà!

Èmi yóò wọn Jakọbu,

èmi ó fọ́n wọn Israẹli.

8 "Juda, àwọn arákùnrin rẹ yóò yìn ,

ọwọ́ rẹ yóò ọrùn àwọn ̀rẹ,

àwọn ọmọkùnrin baba rẹ yóò foríbalẹ̀ fún .

9 49.9,10: Nu 24.9; If 5.5. Ọmọ kìnnìún ni ́, ìwọ Juda,

o darí láti igbó ọdẹ, ọmọ mi.

i kìnnìún, o ba mọ́lẹ̀, o sùn sílẹ̀ i abo kìnnìún,

ta ni ó bẹ́̀, o e dìde?

10 ̀oyè yóò kúrò Juda

bẹ́̀ ni ̀pá-ìṣàkóso yóò kúrò láàrín ẹsẹ̀ rẹ̀,

títí Ṣilo ó ni í yóò fi ,

gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè yóò máa wárí fún un.

11 Yóò so ọmọ ẹṣin rẹ̀ mọ́ igi àjàrà,

àti ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ mọ́ ̀ka ó dára .

Yóò fọ aṣọ rẹ̀ nínú wáìnì

àti ̀rẹ̀ nínú omi-pupa ti èso àjàrà.

12 Ojú rẹ̀ yóò rẹ̀ dòdò ju wáìnì lọ,

eyín rẹ yóò funfun ju omi-ọyàn lọ.

13 "Sebuluni yóò máa gbé etí Òkun,

yóò jẹ́ èbúté fún ọkọ̀ ojú omi,

agbègbè rẹ yóò tàn títí Sidoni.

14 "Isakari jẹ́ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ alágbára

ó dùbúlẹ̀ láàrín agbo àgùntàn.

15 Nígbà ó ibi ìsinmi òun ti dára ,

àti ilẹ̀ rẹ̀ ti ìdẹ̀ra ,

yóò tẹ èjìká rẹ̀ ba láti ru àjàgà,

yóò fi ara rẹ̀ fún iṣẹ́ ipá.

16 "Dani yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀

gẹ́gẹ́ ̀kan nínú àwọn ̀Israẹli.

17 Dani yóò jẹ́ ejò ni pópónà

àti paramọ́lẹ̀ ̀̀,

ó bu ẹṣin jẹ ẹsẹ̀,

ẹni ń gùn ún à le è ṣubú sẹ́yìn.

18 "Mo ń dúró de ìtúsílẹ̀ rẹ, Olúwa.

19 "Ẹgbẹ́ ogun àwọn ẹlẹ́ṣin yóò kọlu Gadi,

ṣùgbọ́n yóò kọlu wọ́n gìgísẹ̀ wọn.

20 "Oúnjẹ Aṣeri yóò dára;

yóò ṣe àsè ó yẹ fún ọba.

21 "Naftali yóò jẹ́ abo àgbọ̀nrín

a sílẹ̀ ó ń ọmọ dáradára.

22 "Josẹfu jẹ́ àjàrà eléso,

àjàrà eléso etí odò,

̀ka rẹ̀ gun orí odi.

23 Pẹ̀ìkorò, àwọn tafàtafà dojú ìjà kọ ́,

wọ́n tafà í pẹ̀ìkanra.

24 Ṣùgbọ́n ọrun rẹ̀ dúró ni agbára,

ọwọ́ agbára rẹ̀ ni a mu lára le,

nítorí ọwọ́ alágbára Jakọbu,

nítorí olùtọ́àti aláàbò àpáta Israẹli,

25 nítorí Ọlọ́run baba rẹ ó ràn ́ lọ́wọ́,

nítorí Olódùmarè ó bùkún

pẹ̀láti ̀run ,

ìbùkún ̀gbìn ó ìsàlẹ̀,

ìbùkún ti ọmú àti ti inú.

26 Ìbùkún baba rẹ pọ̀ púpọ̀

ju ìbùkún àwọn òkè ńlá ìgbàanì,

ju ̀bùn ńlá àwọn òkè láéláé.

Jẹ́ gbogbo èyí sọ̀kalẹ̀ orí Josẹfu,

ìpéǹpéjú ọmọ-aládé láàrín arákùnrin rẹ̀.

27 "Benjamini jẹ́ ìkookò ó burú;

òwúrọ̀ ni ó jẹ ẹran ọdẹ rẹ,

àṣálẹ́, ó pín ìkógun."

28 Gbogbo ìwọ̀nyí ni àwọn ̀Israẹli méjìlá, èyí ni ohun baba wọn sọ fún wọn nígbà ó súre fún wọn, ó fún ẹnìkọ̀̀kan ìbùkún ó tọ́ i.

Ikú Jakọbu

29 Nígbà náà ni ó fún wọn àwọn ìlànà yìí, "Ọjọ́ ikú mi fẹ́́rẹ́. sin ibojì pẹ̀àwọn baba mi inú àpáta ilẹ̀ Hiti ará Efroni. 30 49.30: Gẹ 23.3-20.Ihò àpáta ó ilẹ̀ Makpela, nítòsí Mamre Kenaani, èyí Abrahamu gẹ́gẹ́ ilẹ̀ ìsìnkú lọ́wọ́ Efroni ará Hiti pẹ̀ilẹ̀ rẹ̀. 31 49.31: Gẹ 25.9,10; Gẹ 35.29.Níbẹ̀ ni a sin Abrahamu àti aya rẹ̀ Sara , níbẹ̀ ni a sin Isaaki àti Rebeka aya rẹ̀ , níbẹ̀ ni mo sìnkú Lea . 32 Ilẹ̀ náà àti ihò àpáta ó nínú rẹ̀ ni a lọ́wọ́ ará Hiti."

33 49.33: Ap 7.15. Nígbà Jakọbu ti pàṣẹ yìí fún àwọn ọmọ rẹ̀, ó gbé ẹsẹ̀ rẹ̀ sókè sórí ibùsùn, ó , a ko jọ pọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também