Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 32

Sennakeribu dẹ́rùba Jerusalẹmu

1 32.1: 2Ọb 18.13. Lẹ́yìn gbogbo èyí ti Hesekiah ti fi òtítọ́ ṣe, Sennakeribu ọba Asiria ó gbógun ti Juda. Ó gbógun ti àwọn ìlú ààbò, ó ń ronú láti ṣẹ́gun wọn fún ara rẹ̀. 2 Nígbà Hesekiah i Sennakeribu ti , àti ó fẹ́ láti ogun sílẹ̀ lórí Jerusalẹmu, 3 Ó gbèrò pẹ̀àwọn ìjòyè rẹ̀ àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ láti di orísun omi ìta ìlú ńlá, wọ́n ràn án lọ́wọ́. 4 ̀pọ̀ ogun ọkùnrin péjọ, wọ́n gbogbo àwọn orísun àti àwọn omi ń sàn ó ń sàn gba ti ilẹ̀ náà. "ni ó àwọn ọba Asiria fi wọ́n ̀pọ̀ omi?" Wọ́n . 5 Nígbà náà ó ṣiṣẹ́ gidigidi títún gbogbo ara ògiri ó ti bàjẹ́ ṣe, ó ń kọ́ àwọn ilé ìṣọ́ gíga sókè rẹ̀. Ó kọ́ ògiri mìíràn ìta. Ó tún pẹ̀ibi ìtẹ́ilé ti ìlú ńlá Dafidi. Ó ṣe ̀pọ̀ iye ohun ìjà àti àwọn àpáta.

6 Ó yan àwọn ìjòyè ológun sórí àwọn ènìyàn, ó wọ́n jọ, níwájú rẹ̀ ìbámu ìlú ńlá ti Dafidi. Ó ki wọ́n láyà pẹ̀àwọn ̀rọ̀ wọ̀nyí: 7 "jẹ́ alágbára, àti ìgboyà. ṣe bẹ̀tàbí ìrẹ̀wẹ̀ọkàn nítorí ọba Asiria àti ̀pọ̀ ọmọ-ogun pẹ̀rẹ̀, nítorí agbára ńlá pẹ̀wa ju òun lọ. 8 Agbára ẹran-ara nìkan ni ó pẹ̀rẹ̀ ṣùgbọ́n, Olúwa Ọlọ́run wa pẹ̀wa láti ràn lọ́wọ́ àti láti ja ìjà wa." Àwọn ènìyàn ìgboyà láti ara ohun Hesekiah ọba Juda .

9 32.9-21: 2Ọb 18.17–19.37. Lẹ́yìn ìgbà Sennakeribu ọba Asiria àti gbogbo àwọn ogun rẹ̀ ń gbógun Lakiṣi. Ó rán àwọn ìjòyè rẹ̀ Jerusalẹmu pẹ̀iṣẹ́ fún Hesekiah ọba Juda àti fún gbogbo àwọn ènìyàn Juda ó níbẹ̀:

10 "Èyí ni ohun Sennakeribu ọba Asiria , Lórí ni ̀yin gbé ìgbẹ́kẹ̀yín , ̀yin fi dúró Jerusalẹmu lábẹ́ ìgbógun ?11 Nígbà Hesekiah , Olúwa Ọlọ́run wa yóò gbà kúrò lọ́wọ́ ọba Asiria,ó ń ṣì yín tọ́ ṣọ́, fún ebi àti òǹgbẹ. 12 Ṣé Hesekiah fúnra rẹ̀ àwọn ọlọ́run ibi gíga àti àwọn pẹpẹ kúrò, ó ń fún Juda àti Jerusalẹmu , ̀yin gbọdọ̀ sìn níwájú pẹpẹ kan àti láti sun àwọn ẹbọ lórí rẹ̀’?

13 "Ṣé ̀yin mọ̀ ohun èmi àti àwọn baba mi ti ṣe gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ mìíràn? Ǹjẹ́ àwọn Ọlọ́run àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn agbára láti gba ilẹ̀ wọn kúrò lọ́wọ́ mi? 14 Ta ni nínú gbogbo àwọn òrìṣà orílẹ̀-èdè wọ̀nyí àwọn baba mi ti parun, ó le gbà ènìyàn rẹ̀ lọ́wọ́ mi, Ọlọ́run yín yóò fi le gbà yín lọ́wọ́ mi? 15 Nísinsin yìí, ṣe jẹ́ Hesekiah ó tàn yín àti ṣì yín tọ́ ṣọ́báyìí. ṣe gbà á gbọ́, nítorí ọlọ́run orílẹ̀-èdè mìíràn tàbí ìjọba ó agbára láti gba àwọn ènìyàn rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ mi tàbí lọ́wọ́ àwọn baba mi, mélòó mélòó wa ni Ọlọ́run yín yóò gbà yín kúrò lọ́wọ́ mi!"

16 Àwọn ìjòyè Sennakeribu sọ̀rọ̀ síwájú i ìlòdì Olúwa Ọlọ́run àti ìránṣẹ́ rẹ̀ Hesekiah. 17 Ọba pẹ̀kọ àwọn ìwé bíbú Olúwa Ọlọ́run Israẹli àti sísọ èyí ìlòdì : "gẹ́gẹ́ àwọn ọlọ́run àwọn ènìyàn ilẹ̀ mìíràn ṣe gba àwọn ènìyàn wọn kúrò lọ́wọ́ mi. Bẹ́̀ ni Ọlọ́run Hesekiah yóò gba àwọn ènìyàn rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ mi." 18 Lẹ́yìn náà wọ́n jáde èdè Heberu àwọn ènìyàn Jerusalẹmu ó lára ògiri, láti ọjọ́ fún wọn, ki wọn ó fi agbára ìlú náà. 19 Wọ́n sọ̀rọ̀ nípa Ọlọ́run Jerusalẹmu wọ́n ti ṣe nípa àwọn ọlọ́run àwọn ènìyàn mìíràn ti àgbáyé, iṣẹ́ ọwọ́ àwọn ènìyàn.

20 Ọba Hesekiah àti wòlíì Isaiah ọmọ Amosi sọkún jáde nínú àdúrà ̀run nípa èyí. 21 Olúwa ran angẹli ó pa gbogbo àwọn ọmọ-ogun àti àwọn adarí àti àwọn ìjòyè ó nínú àgọ́ ọba Asiria run. Bẹ́̀ ni ó padà ilẹ̀ rẹ̀ ìtìjú. Nígbà ó lọ sínú ilé ọlọ́run rẹ̀, díẹ̀ nínú àwọn ọmọ rẹ̀ e lulẹ̀ pẹ̀idà.

22 Bẹ́̀ ni Olúwa yọ Hesekiah àti àwọn ènìyàn Jerusalẹmu kúrò lọ́wọ́ Sennakeribu ọba Asiria àti lọ́wọ́ gbogbo àwọn mìíràn. Ó tọ́wọn gbogbo ̀. 23 ̀pọ̀ ọrẹ Jerusalẹmu fún Olúwa àti àwọn ̀bùn iyebíye fún Hesekiah ọba Juda. Ó gbéga lójú gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè lẹ́yìn náà.

Ìgbéraga, àṣeyọrí àti ikú Hesekiah

24 32.24-33: 2Ọb 20.1-21. ọjọ́ wọ́n Hesekiah ṣe àárẹ̀, ó dójú ikú. Ó gbàdúrà Olúwa ó a lóhùn, ó fún un àmì àgbàyanu. 25 Ṣùgbọ́n ọkàn Hesekiah ṣe ìgbéraga, kọbi ara i inú rere a fihàn án. Nítorí náà, ìbínú Olúwa lórí rẹ̀ àti lórí Juda àti Jerusalẹmu. 26 Nígbà náà ni Hesekiah ronúpìwàdà ti ìgbéraga ọkàn rẹ̀, àwọn ènìyàn Jerusalẹmu ṣe bẹ́̀, nítorí náà, ìbínú Olúwa orí wọn ìgbà àwọn ọjọ́ Hesekiah.

27 Hesekiah ̀pọ̀ ọrọ̀ ńlá àti ọlá, ó ṣe àwọn ilé ìṣúra fún fàdákà àti wúrà rẹ̀ àti fún àwọn òkúta iyebíye rẹ̀, àwọn tùràrí olóòórùn dídùn àwọn àpáta àti gbogbo oríṣìí nǹkan iyebíye. 28 Ó kọ́ àwọn ilé pẹ̀láti tọ́àwọn ọkà àwọn wọ́n ka, ọtí tuntun àti òróró; ó ṣe àwọn àtíbàbà fún oríṣìí àwọn ẹran ̀sìn àti àwọn àṣémọ́ fun àwọn ̀wọ̀ ẹran. 29 Ó kọ́ àwọn ìletò, ó gba ̀pọ̀ àwọn ̀wọ́ ẹran àti agbo ẹran, nítorí Ọlọ́run ti fún un ̀pọ̀ ọrọ̀ ńlá.

30 Hesekiah ni ó ojú ìṣúra apá òkè ti orísun Gihoni. Ó gbe gba ìsàlẹ̀ ìhà ìwọ oòrùn ìlú ńlá ti Dafidi. Ó ṣe àṣeyọrí rere nínú gbogbo ohun ó dáwọ́. 31 Ṣùgbọ́n nígbà a rán àwọn oníṣẹ́ ọba láti Babeli láti bi í lérè nípa àmì ìyanu ó ṣẹlẹ̀ , Ọlọ́run fi sílẹ̀ láti dán an àti láti mọ gbogbo nǹkan ó lọ́kàn rẹ̀.

32 Gbogbo iṣẹ́ yòókù ti ìjọba Hesekiah àti àwọn ìṣe rẹ̀, ìfarajì rẹ̀ ni a kọ sínú ìwé ìran wòlíì Isaiah ọmọ Amosi nínú ìwé àwọn ọba Juda àti Israẹli 33 Hesekiah sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀. A sin ín sórí òkè níbi àwọn ibojì àwọn àtẹ̀Dafidi . Gbogbo Juda àti àwọn ènìyàn Jerusalẹmu ni ó bu ọlá fún un nígbà ó . Manase ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também