Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 28

Ahasi ọba Juda

1 28.1-4: 2Ọb 16.2-4. Ahasi jẹ́ ẹni ogún ọdún nígbà ó bẹ̀rẹ̀ ìjọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́rìndínlógún. Gẹ́gẹ́ i Dafidi baba rẹ̀ ṣe ohun rere ojú Olúwa. 2 Ó rìn ̀àwọn ọba Israẹli ó ṣe ère dídá fún ìsìn Baali 3 Ó sun ẹbọ àfonífojì Hinnomu, ó sun àwọn ọmọ rẹ̀ nínú iná, gẹ́gẹ́ ohun ìríra àwọn orílẹ̀-èdè Olúwa jáde níwájú àwọn ọmọ Israẹli 4 Ó ẹbọ, ó sun tùràrí ibi gíga wọ́n lórí òkè kékeré àti lábẹ́ gbogbo igi tútù.

5 Nítorí náà, Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ fi ọba Siria lọ́wọ́. Àwọn ará Siria pa á run, wọ́n púpọ̀ nínú àwọn ènìyàn rẹ̀ gẹ́gẹ́ ẹlẹ́wọ̀n, wọ́n wọn Damasku.

Ó tún fi ọwọ́ ọba Israẹli pẹ̀, ẹni ó wọn ìgbèkùn púpọ̀ ó pa wọ́n ìpakúpa. 6 ọjọ́ kan Peka, ọmọ Remaliah, pa ̀kẹ́ mẹ́(120,000) àwọn ọmọ-ogun Juda nítorí Juda ti kọ Olúwa Ọlọ́run baba wọn sílẹ̀. 7 Sikri àti Efraimu alágbára pa Maaseiah ọmọ ọba, Aṣrikamu ìjòyè ó ìkáwọ́ ilé ọba, àti Elkana igbákejì ọba. 8 Àwọn ọmọ Israẹli ìgbèkùn lára àwọn arákùnrin wọn ̀kẹ́ mẹ́wàá (200,000) àwọn aya wọn, àwọn ọmọkùnrin àti obìnrin wọn tún ̀pọ̀ ìkógun, èyí wọn padà lọ Samaria.

9 Ṣùgbọ́n wòlíì Olúwa orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Odedi níbẹ̀, ó jáde lọ láti lọ pàdé ogun nígbà ó padà Samaria. Ó fún wọn , "Nítorí Olúwa, Ọlọ́run baba yín bínú Juda ó fi wọ́n yín lọ́wọ́. Ṣùgbọ́n ̀yin pa wọ́n ìpa oró ó de òkè ̀run. 10 Nísinsin yìí, ̀yin ń pète láti ọkùnrin àti obìnrin Juda àti Jerusalẹmu ṣe gẹ́gẹ́ ẹrú yín, ̀yin ha jẹ̀bi Olúwa Ọlọ́run yín, àní ̀yin? 11 Nísinsin yìí gbọ́ tèmi! rán àwọn ìgbèkùn ̀yin ti gẹ́gẹ́ àwọn ẹlẹ́wọ̀n padà nítorí ìbínú kíkan Olúwa ń bẹ lórí yín."

12 Lẹ́yìn náà, díẹ̀ nínú àwọn olórí Efraimu, Asariah ọmọ Jehohanani, Berekiah ọmọ Meṣilemoti, Jehiskiah ọmọ Ṣallumu, àti Amasa ọmọ Hadlai, dìde àwọn o ti ogun náà bọ̀. 13 Wọn si , "Ìwọ gbọdọ̀ àwọn ẹlẹ́wọ̀n síbí," "tàbí àwa ti jẹ̀bi níwájú Olúwa, ṣe ̀yin ń gbèrò láti fi kún ̀ṣẹ̀ àti ̀bi wa ni: nítorí ̀bi wa ti tóbi púpọ̀, ìbínú rẹ̀ kíkan lórí Israẹli."

14 Bẹ́̀ ni àwọn ológun àwọn ẹlẹ́wọ̀n àti ìkógun sílẹ̀ níwájú àwọn ìjòyè àti gbogbo ìjọ ènìyàn. 15 Àwọn ọkùnrin a pẹ̀orúkọ náà dìde, wọn àwọn ìgbèkùn náà, wọ́n fi ìkógun náà wọ̀ gbogbo àwọn ó ìhòhò nínú wọn, wọ́n wọ̀ wọ́n aṣọ, wọ́n bọ̀ wọ́n bàtà, wọ́n fún wọn oúnjẹ àti ohun mímu, wọ́n fi òróró kùn wọ́n ara, wọ́n gbogbo àwọn ó jẹ́ aláìlera nínú wọ́n sórí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́. Bẹ́̀ ni wọ́n wọn padà ̀dọ̀ àwọn arákùnrin wọn Jeriko, ìlú ̀pẹ, wọ́n padà Samaria.

16 àkókò ìgbà náà, ọba Ahasi ránṣẹ́ ọba Asiria fún ìrànlọ́wọ́. 17 Àwọn ará Edomu tún padà láti kọlu Juda wọn àwọn ẹlẹ́wọ̀n lọ. 18 Nígbà àwọn ará Filistini ti jagun ìlú pẹ̀tẹ́lẹ̀ wọ́n àti síhà gúúsù Juda. Wọ́n ṣẹ́gun wọ́n gba Beti-Ṣemeṣi, Aijaloni àti Gederoti, àti Soko, Timna, a ri Gimiso, pẹ̀ìletò wọn. 19 Olúwa rẹ Juda sílẹ̀ nítorí Ahasi ọba Israẹli, nítorí ó sọ Juda di aláìní ìrànlọ́wọ́, ó ṣe ìrékọjá gidigidi Olúwa. 20 Tiglat-Pileseri ọba Asiria ̀dọ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ó fún ìpọ́njú dípò ìrànlọ́wọ́. 21 Ahasi díẹ̀ nínú ìní ilé Olúwa àti láti ilé ọba àti láti ̀dọ̀ ọba ó fi wọ́n fún ọba Asiria: ṣùgbọ́n èyí ràn wọ́n lọ́wọ́.

22 àkókò ìpọ́njú rẹ̀ ọba Ahasi di aláìṣòótọ́ Olúwa. 23 Ó ẹbọ òrìṣà àwọn Damasku, ẹni ó ṣẹ́gun wọn, nítorí ó , "Nítorí àwọn òrìṣà àwọn ọba Siria ti ràn wọ́n lọ́wọ́ wọn ó ràn lọ́wọ́." Ṣùgbọ́n àwọn ni ìparun rẹ̀ àti ti gbogbo Israẹli.

24 Ahasi gbogbo ohun èlò láti ilé Olúwa jọ ó wọn lọ. Ó ti ìlẹ̀kùn ilé Olúwa ó tẹ́ pẹpẹ fún ara rẹ̀ gbogbo igun Jerusalẹmu. 25 gbogbo ìlú Juda ó kọ́ ibi gíga láti sun ẹbọ fún àwọn ọlọ́run mìíràn. ó Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wọn bínú.

26 Ìyókù iṣẹ́ ìjọba rẹ̀ àti gbogbo ̀rẹ̀, láti ìbẹ̀rẹ̀ títí òpin, ni a kọ sínú ìwé àwọn ọba Juda àti ti Israẹli. 27 28.27: 2Ọb 16.20.Ahasi sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀ a sin ín ìlú Jerusalẹmu ṣùgbọ́n wọn un sínú àwọn isà òkú àwọn ọba Israẹli. Hesekiah ọmọ rẹ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também