Pular para o conteúdo
Publicidade

Luku 20

Wọ́n béèrè nípa àṣẹ Jesu

1 20.1-8: Mt 21.23-27; Mk 11.27-33. ọjọ́ kan, ó ti ń kọ́ àwọn ènìyàn tẹmpili ó ń wàásù ìyìnrere, àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn akọ̀, pẹ̀àwọn àgbàgbà dìde i. 2 20.2: Jh 2.18.Wọ́n fún un , "Sọ fún wa, àṣẹ wo ni ìwọ fi ń ṣe nǹkan wọ̀nyí? Tàbí ta ni ó fún àṣẹ yìí?"

3 Ó dáhùn ó fún wọn , "Èmi pẹ̀yóò bi yín léèrè ̀rọ̀ kan; fi ìdáhùn fún mi. 4 Ìtẹ̀bọmi Johanu, láti ̀run ni tàbí láti ̀dọ̀ ènìyàn?"

5 Wọ́n ara wọn gbèrò , "àwa , Láti ̀run ni,òun yóò , Èéṣe ̀yin fi gbà á gbọ́?’ 6 20.6: Mt 14.5; Lk 7.29.Ṣùgbọ́n àwa , Láti ̀dọ̀ ènìyàn,gbogbo ènìyàn ni yóò sọ òkúta, nítorí wọ́n gbàgbọ́ , wòlíì ni Johanu."

7 Wọ́n dáhùn , "Àwa mọ̀ ibi ó ti ."

8 Jesu fún wọn , "Ǹjẹ́ èmi yóò fún yín àṣẹ èmi fi ń ṣe nǹkan wọ̀nyí."

Òwe àwọn ayálégbé

9 20.9-19: Mt 21.33-46; Mk 12.1-12. 20.9: Isa 5.1-7; Mt 25.14. Nígbà náà ni ó bẹ̀rẹ̀ í pa òwe yìí fún àwọn ènìyàn , "Ọkùnrin kan gbin ọgbà àjàrà kan, ó fi ṣe àgbàtọ́fún àwọn olùṣọ́gbà, ó lọ àjò fún ìgbà pípẹ́. 10 Nígbà ó àkókò, ó rán ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ kan àwọn olùṣọ́gbà náà, wọn fún un nínú èso ọgbà àjàrà náà, ṣùgbọ́n àwọn alágbàtọ́ú, wọ́n rán an padà lọ́wọ́ òfo. 11 Ó tún rán ọmọ ̀dọ̀ mìíràn, wọ́n ú pẹ̀, wọ́n jẹ ́ , wọ́n rán an padà lọ́wọ́ òfo. 12 Ó tún rán ̀kẹta: wọ́n a lọ́gbẹ́ pẹ̀, wọ́n í jáde.

13 "Nígbà náà ni Olúwa ọgbà àjàrà , Èwo ni èmi ó ṣe? Èmi ó rán ọmọ mi àyànfẹ́ lọ: bóyá nígbà wọ́n i, wọn yóò bu ọlá fún un.

14 "Ṣùgbọ́n nígbà àwọn alágbàtọ́náà i, wọ́n ara wọn gbèrò , Èyí ni àrólé; , jẹ́ a pa á, ogún rẹ̀ jẹ́ ti wa. 15 Bẹ́̀ ni wọ́n í jáde sẹ́yìn ọgbà àjàrà, wọ́n pa á.

"Ǹjẹ́ kín ni olúwa ọgbà àjàrà náà yóò ṣe wọn? 16 20.16: Ap 13.46; 18.6; 28.28.Yóò , yóò pa àwọn alágbàtọ́náà run, yóò fi ọgbà àjàrà náà fún àwọn ẹlòmíràn."

Nígbà wọ́n gbọ́, wọ́n , "a ri i!"

17 20.17: Sm 118.22-23; Ap 4.11; 1Pt 2.6-7. Nígbà ó wọ́n, ó , "Èwo ha ni èyí a ti kọ̀rẹ̀ :

" Òkúta àwọn ̀mọ̀kọ̀sílẹ̀,

òun náà ni ó di pàtàkì igun ilé?

18 20.18: Isa 8.14-15. Ẹnikẹ́ni ó ṣubú lu òkúta náà yóò fọ́; ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni òun ṣubú , yóò lọ̀ ́ lúúlúú."

19 20.19: Lk 19.47. Àwọn olórí àlùfáà àti àwọn akọ̀ń ̀láti un wákàtí náà; ṣùgbọ́n wọ́n bẹ̀àwọn ènìyàn, nítorí wọ́n mọ̀ , ó pa òwe yìí mọ́ wọn.

Sísan owó orí fún Kesari

20 20.20-26: Mt 22.15-22; Mk 12.13-17. Wọ́n ń ṣọ́ , wọ́n rán àwọn ayọ́lẹ̀wọ́n ṣe ara wọn ẹni olóòtítọ́ ènìyàn, wọn ba à gbá ̀rọ̀ rẹ̀ , wọn ba à fi í agbára àti àṣẹ Baálẹ̀ lọ́wọ́. 21 20.21: Jh 3.2.Wọ́n i, , "Olùkọ́ àwa mọ̀ , ìwọ a máa sọ̀rọ̀ fún ni, ìwọ a máa kọ́ni ó ti tọ́, bẹ́̀ ni ìwọ í ṣe ojúsàájú ẹnìkan ṣùgbọ́n ìwọ ń kọ́ni ̀Ọlọ́run lóòtítọ́. 22 Ǹjẹ́ ó tọ́ fún wa láti máa san owó òde fún Kesari, tàbí tọ́?"

23 Ṣùgbọ́n ó kíyèsi àrékérekè wọn, ó fún wọn , 24 "fi owó idẹ kan hàn . Àwòrán àti àkọlé ti ta ni ó níbẹ̀?"

Wọ́n a lóhùn , "Ti Kesari ni."

25 20.25: Mt 22.23-33; Mk 12.18-27. Ó fún wọn , "Ǹjẹ́ fi ohun i ṣe ti Kesari fún Kesari, àti ohun í ṣe ti Ọlọ́run fún Ọlọ́run."

26 Wọn gbá ̀rọ̀ rẹ̀ níwájú àwọn ènìyàn: ẹnu wọ́n ìdáhùn rẹ̀, wọ́n pa ẹnu wọn mọ́.

Àjíǹde àti ìgbéyàwó

27 20.27-38: Mt 22.23-33; Mk 12.18-27. 20.27: Ap 4.1-2; 23.6-10. Àwọn Sadusi kan tọ̀ ́ , àwọn wọ́n ń àjíǹde òkú wọ́n bi í, 28 20.28: De 25.5., "Olùkọ́, Mose kọ̀fún wa , arákùnrin ẹnìkan , àìlọ́mọ, ó aya, arákùnrin rẹ̀ ṣú aya rẹ̀ lópó, ó gbé irú-ọmọ dìde fún arákùnrin rẹ̀. 29 Ǹjẹ́ àwọn arákùnrin méje kan ti ; èkínní gbé ìyàwó, ó àìlọ́mọ. 30 Èkejì ṣú u lópó: òun àìlọ́mọ. 31 ̀kẹta ṣú u lópó: gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni àwọn méjèèje pẹ̀: wọn fi ọmọ sílẹ̀, wọ́n . 32 Nígbẹ̀yìn pátápátá obìnrin náà pẹ̀. 33 Ǹjẹ́ àjíǹde òkú, aya ti ta ni yóò ha ṣe nínú wọn? Nítorí àwọn méjèèje ni ó à ni í aya."

34 Jesu dáhùn ó fún wọn , "Àwọn ọmọ ayé yìí a máa gbéyàwó, wọn a máa fa ìyàwó fún ni. 35 Ṣùgbọ́n àwọn a yẹ láti jogún ìyè ayérayé náà, àti àjíǹde kúrò nínú òkú, wọn í gbéyàwó, wọn í í fa ìyàwó fún ni. 36 Nítorí wọn mọ́; nítorí wọn àwọn angẹli dọ́gba; àwọn ọmọ Ọlọ́run ni wọ́n, nítorí wọ́n di àwọn ọmọ àjíǹde. 37 20.37: Ek 3.6.ti a ń àwọn òkú dìde, Mose tìkára rẹ̀ ti fihàn nínú igbó, nígbà ó pe Olúwa ni Ọlọ́run Abrahamu, àti Ọlọ́run Isaaki, àti Ọlọ́run Jakọbu. 38 Bẹ́̀ ni òun í ṣe Ọlọ́run àwọn òkú, ṣe ti àwọn alààyè, nítorí gbogbo wọn láààyè fún un."

39 20.39: Mk 12.28. Nígbà náà ni àwọn kan nínú àwọn akọ̀a lóhùn, , "Olùkọ́ ìwọ rere!" 40 20.40: Mk 12.34; Mt 22.46.Wọn jẹ́ bi í léèrè ̀rọ̀ kan mọ́.

Ọmọ ta ni Jesu n ṣe

41 20.41-44: Mt 22.41-45; Mk 12.35-37; Sm 110.1. Ó fún wọn , "Èéṣe wọ́n fi ń , ọmọ Dafidi ni Kristi? 42 Dafidi tìkára rẹ̀ nínú ìwé Saamu :

" Olúwa sọ fún Olúwa mi :

"Ìwọ jókòó ọwọ́ ̀tún mi

43 títí èmi ó fi sọ àwọn ̀rẹ

di àpótí ìtìsẹ̀ rẹ." 

44 Ǹjẹ́ Dafidi é Olúwa.Òun ha ti ṣe jẹ́ ọmọ rẹ̀?"

45 20.45-47: Mk 12.38-40; Mt 23.6-7; Lk 11.43; 14.7-11. Ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ etí gbogbo ènìyàn , 46 "máa kíyèsára lọ́dọ̀ àwọn akọ̀, wọ́n fẹ́ láti máa rìn nínú aṣọ gígùn, wọ́n fẹ́ ìkíni ọjà, àti ibùjókòó ọlá nínú Sinagọgu, àti ipò ọlá ibi àsè; 47 Àwọn ó jẹ ilé àwọn opó run, wọ́n ń gbàdúrà gígùn fún àṣehàn, àwọn wọ̀nyí náà ni yóò jẹ̀bi pọ̀."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também